Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Àkọsílẹ̀ Ìhìn Rere Máàkù

Orí

1 2 3 4 5 6 7 8 9 10 11 12 13 14 15 16

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

  • 1

    • Jòhánù Onírìbọmi ń wàásù (1-8)

    • Jésù ṣèrìbọmi (9-11)

    • Sátánì dán Jésù wò (12, 13)

    • Jésù bẹ̀rẹ̀ sí í wàásù ní Gálílì (14, 15)

    • Ó pe àwọn tó kọ́kọ́ di ọmọ ẹ̀yìn (16-20)

    • Ó lé ẹ̀mí àìmọ́ jáde (21-28)

    • Jésù wo ọ̀pọ̀ èèyàn sàn ní Kápánáúmù (29-34)

    • Ó gbàdúrà níbi tó dá (35-39)

    • Ó wo adẹ́tẹ̀ sàn (40-45)

  • 2

    • Jésù wo alárùn rọpárọsẹ̀ sàn (1-12)

    • Jésù pe Léfì (13-17)

    • Wọ́n béèrè nípa ààwẹ̀ lọ́wọ́ rẹ̀ (18-22)

    • Jésù ni “Olúwa Sábáàtì” (23-28)

  • 3

    • Ó wo ọkùnrin tí ọwọ́ rẹ̀ rọ sàn (1-6)

    • Èrò rẹpẹtẹ wá sí èbúté (7-12)

    • Àwọn àpọ́sítélì méjìlá (13-19)

    • Ọ̀rọ̀ òdì sí ẹ̀mí mímọ́ (20-30)

    • Ìyá Jésù àti àwọn arákùnrin rẹ̀ (31-35)

  • 4

    • ÀWỌN ÀPÉJÚWE NÍPA ÌJỌBA NÁÀ (1-34)

      • Afúnrúgbìn (1-9)

      • Ìdí tí Jésù fi lo àwọn àpèjúwe (10-12)

      • Ó ṣàlàyé ìtumọ̀ àpèjúwe afúnrúgbìn (13-20)

      • A kì í gbé fìtílà sábẹ́ apẹ̀rẹ̀ (21-23)

      • Òṣùwọ̀n tí ẹ fi ń díwọ̀n (24, 25)

      • Afúnrúgbìn tó sùn (26-29)

      • Hóró músítádì (30-32)

      • Ó ń lo àpèjúwe (33, 34)

    • Jésù mú kí ìjì dáwọ́ dúró (35-41)

  • 5

    • Jésù lé àwọn ẹ̀mí èṣù lọ sínú ẹlẹ́dẹ̀ (1-20)

    • Ọmọbìnrin Jáírù; obìnrin kan fọwọ́ kan aṣọ àwọ̀lékè Jésù (21-43)

  • 6

    • Wọn ò tẹ́wọ́ gba Jésù ní ìlú rẹ̀ (1-6)

    • Ó fún àwọn Méjìlá náà ní ìtọ́ni nípa iṣẹ́ ìwàásù (7-13)

    • Wọ́n pa Jòhánù Onírìbọmi (14-29)

    • Jésù bọ́ 5,000 èèyàn (30-44)

    • Jésù rìn lórí omi (45-52)

    • Ó ṣe ìwòsàn ní Jẹ́nẹ́sárẹ́tì (53-56)

  • 7

    • Ó tú àṣírí àwọn àṣà àtọwọ́dọ́wọ́ àwọn èèyàn (1-13)

    • Inú ọkàn ni ohun tó ń sọni di aláìmọ́ ti ń wá (14-23)

    • Ìgbàgbọ́ obìnrin tó jẹ́ ọmọ ilẹ̀ Foníṣíà ní Síríà (24-30)

    • Ó wo adití sàn (31-37)

  • 8

    • Jésù bọ́ 4,000 èèyàn (1-9)

    • Wọ́n béèrè àmì (10-13)

    • Ìwúkàrà àwọn Farisí àti ti Hẹ́rọ́dù (14-21)

    • Ó wo afọ́jú kan sàn ní Bẹtisáídà (22-26)

    • Pétérù pè é ní Kristi (27-30)

    • Àsọtẹ́lẹ̀ nípa ikú Jésù (31-33)

    • Ojúlówó ọmọ ẹ̀yìn (34-38)

  • 9

    • A yí Jésù pa dà di ológo (1-13)

    • Ó wo ọmọkùnrin tí ẹ̀mí èṣù ń yọ lẹ́nu sàn (14-29)

      • Ohun gbogbo ṣeé ṣe fún ẹni tó ní ìgbàgbọ́ (23)

    • Jésù tún sọ tẹ́lẹ̀ nípa ikú rẹ̀ (30-32)

    • Àwọn ọmọ ẹ̀yìn ń jiyàn nípa ẹni tó tóbi jù (33-37)

    • Ẹni tí kò bá ta kò wá, tiwa ló ń ṣe (38-41)

    • Àwọn ohun ìkọ̀sẹ̀ (42-48)

    • “Ẹ ní iyọ̀ nínú ara yín” (49, 50)

  • 10

    • Ìgbéyàwó àti ìkọ̀sílẹ̀ (1-12)

    • Jésù súre fún àwọn ọmọdé (13-16)

    • Ìbéèrè ọkùnrin ọlọ́rọ̀ (17-25)

    • Àwọn ohun tí a yááfì torí Ìjọba náà (26-31)

    • Jésù tún sọ tẹ́lẹ̀ nípa ikú rẹ̀ (32-34)

    • Ohun tí Jémíìsì àti Jòhánù béèrè (35-45)

      • Jésù fi ẹ̀mí rẹ̀ ṣe ìràpadà fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ èèyàn (45)

    • Ó wo Báátíméù afọ́jú sàn (46-52)

  • 11

    • Jésù gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọnú ìlú (1-11)

    • Ó gégùn-ún fún igi ọ̀pọ̀tọ́ (12-14)

    • Jésù fọ tẹ́ńpìlì mọ́ (15-18)

    • Ohun tí a rí kọ́ lára igi ọ̀pọ̀tọ́ tó rọ (19-26)

    • Wọ́n béèrè ẹni tó fún Jésù ní àṣẹ (27-33)

  • 12

    • Àpèjúwe àwọn tó ń dáko tí wọ́n sì pààyàn (1-12)

    • Ọlọ́run àti Késárì (13-17)

    • Ìbéèrè nípa àjíǹde (18-27)

    • Àṣẹ méjì tó tóbi jù (28-34)

    • Ṣé ọmọ Dáfídì ni Kristi? (35-37a)

    • Ó ní kí wọ́n ṣọ́ra fún àwọn akọ̀wé òfin (37b-40)

    • Opó aláìní fi ẹyọ owó méjì sílẹ̀ (41-44)

  • 13

    • ÌPARÍ È ÀWỌN NǸKAN (1-37)

      • Ogun, ìmìtìtì ilẹ̀, àìtó oúnjẹ (8)

      • A máa wàásù ìhìn rere (10)

      • Ìpọ́njú ńlá (19)

      • Ọmọ èèyàn ń bọ̀ (26)

      • Àpèjúwe igi ọ̀pọ̀tọ́ (28-31)

      • Ẹ máa ṣọ́nà (32-37)

  • 14

    • Àwọn àlùfáà gbìmọ̀ pọ̀ láti pa Jésù (1, 2)

    • Ó da òróró onílọ́fínńdà sórí Jésù (3-9)

    • Júdásì da Jésù (10, 11)

    • Ìrékọjá tó gbẹ̀yìn (12-21)

    • Jésù fi Oúnjẹ Alẹ́ Olúwa lọ́lẹ̀ (22-26)

    • Ó sọ tẹ́lẹ̀ pé Pétérù máa sẹ́ òun (27-31)

    • Jésù gbàdúrà ní Gẹ́tísémánì (32-42)

    • Wọ́n mú Jésù (43-52)

    • Wọ́n gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀ níwájú Sàhẹ́ndìrìn (53-65)

    • Pétérù sẹ́ Jésù (66-72)

  • 15

    • Jésù dé iwájú Pílátù (1-15)

    • Wọ́n fi ṣẹlẹ́yà ní gbangba (16-20)

    • Wọ́n kàn án mọ́gi ní Gọ́gọ́tà (21-32)

    • Ikú Jésù (33-41)

    • Wọ́n sìnkú Jésù (42-47)

  • 16

    • Jésù jíǹde (1-8)