Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Orísun Ayọ̀ Wa

Orísun Ayọ̀ Wa

(Sáàmù 16:11)

Wà á jáde:

  1. 1. Àwọn ìràwọ̀ lọ salalu lójú ọ̀run.

    Bójúmọ́ bá sì ti wá mọ́,

    Oòrùn á tún yọ.

    O dá ilẹ̀ àti omi,

    Gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ rẹ ló ń mú inú rẹ dùn.

    (ÈGBÈ)

    Inú wa ń dùn sí iṣẹ́ rẹ,

    A sì ń wàásù ìhìn rere,

    Ayé tuntun ti dé tán.

    A mọ̀ pé o nífẹ̀ẹ́ wa gan-an,

    Èyí ló ń múnú wa dùn jù.

    Jèhófà, Ọlọ́run wa

    Lorísun ayọ̀ wa.

  2. 2. Jèhófà, ọ̀pọ̀ nǹkan lò ń ṣe

    Tó ń fún wa láyọ̀.

    A lè gbọ́ràn, a lè ríran

    A tún lè ronú.

    Èrò rere lo ní sí wa,

    O fẹ́ ká wà láàyè láéláé,

    O fẹ́ ká láyọ̀.

    (ÈGBÈ)

    Inú wa ń dùn sí iṣẹ́ rẹ,

    A sì ń wàásù ìhìn rere,

    Ayé tuntun ti dé tán.

    A mọ̀ pé o nífẹ̀ẹ́ wa gan-an,

    Èyí ló ń múnú wa dùn jù.

    Jèhófà, Ọlọ́run wa

    Lorísun ayọ̀ wa.

    (ÀSOPỌ̀)

    Ikú ìrúbọ Ọmọ rẹ

    Ló ń jẹ́ ká láyọ̀.

    Ẹ̀bùn yìí ló jẹ́ ká ní ìrètí

    Ayọ̀ tí kò lópin.

    (ÈGBÈ)

    Inú wa ń dùn sí iṣẹ́ rẹ

    A sì ń wàásù ìhìn rere,

    Ayé tuntun ti dé tán.

    A mọ̀ pé o nífẹ̀ẹ́ wa gan-an

    Èyí ló ń múnú wa dùn jù.

    Jèhófà, Ọlọ́run wa

    Lorísun ayọ̀ wa.

    (ÈGBÈ)

    Inú wa ń dùn sí iṣẹ́ rẹ

    A sì ń wàásù ìhìn rere,

    Ayé tuntun ti dé tán.

    A mọ̀ pé o nífẹ̀ẹ́ wa gan-an

    Èyí ló ń múnú wa dùn jù.

    Jèhófà, Ọlọ́run wa

    Lorísun ayọ̀ wa.