Ìsọ̀rí 4
“Ọlọ́run Jẹ́ Ìfẹ́”
Nínú gbogbo ànímọ́ tí Jèhófà ní, ìfẹ́ ló gba iwájú. Òun ló sì fani mọ́ra jù lọ. Bí a ó ṣe máa gbé apá mélòó kan lára ànímọ́ tó dà bí ìṣúra iyebíye yìí yẹ̀ wò, á ó máa rí ìdí tí Bíbélì fi sọ pé “Ọlọ́run jẹ́ ìfẹ́.”—1 Jòhánù 4:8.
NÍ APÁ YÌÍ
ORÍ 24
Kò Sóhun Tó Lè “Yà Wá Kúrò Nínú Ìfẹ́ Ọlọ́run”
Irọ́ gbuu ni pé Ọlọ́run kò lè nífẹ̀ẹ́ rẹ láé tàbí pé o ò wúlò. Wo ìdí tó fi jẹ́ bẹ́ẹ̀.
ORÍ 25
“Ìyọ́nú Oníjẹ̀lẹ́ńkẹ́ ti Ọlọ́run Wa”
Ọ̀nà wo ni ọwọ́ tí Ọlọ́run fi ń mú ẹ fi dà bí ọwọ́ tí ìyá fi ń mú ọmọ rẹ̀?
ORÍ 26
Ọlọ́run Tó “Ṣe Tán Láti Dárí Jini”
Tó bá jẹ́ Ọlọ́run máa ń rántí gbogbo nǹkan, báwo ló ṣe lè dárí jini kò si gbàgbé ẹ̀?
ORÍ 30
“Máa Bá A Lọ ní Rírìn Nínú Ìfẹ́”
Ìwé Kọ́ríńtì kìíní jẹ́ ká mọ ọ̀nà mẹ́rìnlá tá a lè gbà fi ìfẹ́ hàn.