Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Ìsọ̀rí 4

“Ọlọ́run Jẹ́ Ìfẹ́”

“Ọlọ́run Jẹ́ Ìfẹ́”

Nínú gbogbo ànímọ́ tí Jèhófà ní, ìfẹ́ ló gba iwájú. Òun ló sì fani mọ́ra jù lọ. Bí a ó ṣe máa gbé apá mélòó kan lára ànímọ́ tó dà bí ìṣúra iyebíye yìí yẹ̀ wò, á ó máa rí ìdí tí Bíbélì fi sọ pé “Ọlọ́run jẹ́ ìfẹ́.”—1 Jòhánù 4:8.

NÍ APÁ YÌÍ

ORÍ 23

“Òun Ni Ó Kọ́kọ́ Nífẹ̀ẹ́ Wa”

Kí ni ọ̀rọ̀ náà, “Ọlọ́run jẹ́ ìfẹ́” túmọ̀ sí?

ORÍ 24

Kò Sóhun Tó Lè “Yà Wá Kúrò Nínú Ìfẹ́ Ọlọ́run”

Irọ́ gbuu ni pé Ọlọ́run kò lè nífẹ̀ẹ́ rẹ láé tàbí pé o ò wúlò. Wo ìdí tó fi jẹ́ bẹ́ẹ̀.

ORÍ 25

“Ìyọ́nú Oníjẹ̀lẹ́ńkẹ́ ti Ọlọ́run Wa”

Ọ̀nà wo ni ọwọ́ tí Ọlọ́run fi ń mú ẹ fi dà bí ọwọ́ tí ìyá fi ń mú ọmọ rẹ̀?

ORÍ 26

Ọlọ́run Tó “Ṣe Tán Láti Dárí Jini”

Tó bá jẹ́ Ọlọ́run máa ń rántí gbogbo nǹkan, báwo ló ṣe lè dárí jini kò si gbàgbé ẹ̀?

ORÍ 27

“Wo Bí Oore Rẹ̀ Ti Pọ̀ Tó!”

Kí ló túmọ̀ sí pé Ọlọ́run jẹ́ ẹni rere?

ORÍ 28

“Ìwọ Nìkan Ni Adúróṣinṣin”

Kí ló dé tí ìdúróṣinṣin Ọlọ́run fi lágbára jú ìṣòtítọ́ rẹ̀ lọ?

ORÍ 29

“Láti Mọ Ìfẹ́ Kristi”

Apá mẹ́ta tí ìfẹ́ Jésù pín sí jẹ́ ká mọ irú ìfẹ́ tí Jèhófà ní dáadáa.

ORÍ 30

“Máa Bá A Lọ ní Rírìn Nínú Ìfẹ́”

Ìwé Kọ́ríńtì kìíní jẹ́ ká mọ ọ̀nà mẹ́rìnlá tá a lè gbà fi ìfẹ́ hàn.