Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Ẹ̀kọ́ 13: Jèhófà Á Jẹ́ Kó O Nígboyà

Ẹ̀kọ́ 13: Jèhófà Á Jẹ́ Kó O Nígboyà

Ṣé ẹ̀rù ti bà ẹ́ rí láti sọ̀rọ̀ nípa Jèhófà? Báwo ni Jèhófà ṣe lè ràn ẹ́ lọ́wọ́ kó o lè nígboyà?

O Tún Lè Wo

ERÉ DI Ọ̀RẸ́ JÈHÓFÀ

Báwo Ni Jèhófà Ṣe Lè Ràn Ẹ́ Lọ́wọ́ Kó O Lè Nígboyà?

Jèhófà á ràn ẹ́ lọ́wọ́ kó o lè nígboyà bí ọ̀dọ́bìnrin ọmọ Ísírẹ́lì yẹn.

ÀWỌN FÍDÍÒ

Kẹ́kọ̀ọ́ Lára Àwọn Ọ̀rẹ́ Jèhófà

Kẹ́kọ̀ọ́ lára àwọn ọ̀rẹ́ Jèhófà tí Bíbélì sọ̀rọ̀ wọn!

Ẹ̀KỌ́ BÍBÉLÌ

Eré Ọwọ́ fún Àwọn Ọmọdé

Lo àwọn eré ọwọ́ tó gbádùn mọ́ni tó dá lórí Bíbélì yìí láti fi kọ́ àwọn ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ nípa ìwà rere.