Fífọ́nnu
Sm 94:4; 1Kọ 13:4; Jem 3:5, 14
Tún wo Owe 21:24; Jer 9:23, 24
Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:
Ond 7:1-7—Jèhófà dín àwọn ọmọ ogun Gídíónì kù sí ọgọ́rùn-ún mẹ́ta (300), kó lè ṣe kedere sí wọn pé Jèhófà ló máa jẹ́ kí wọ́n ṣẹ́gun àwọn ọ̀tá wọn
2Ọb 18:28-35—Senakérúbù tó jẹ́ ọba Ásíríà lo agbẹnusọ rẹ̀ láti fọ́nnu pé Jèhófà kò lè gba Jerúsálẹ́mù sílẹ̀ lọ́wọ́ Ásíríà