Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Máa Ran Àwọn Èèyàn Lọ́wọ́

Máa Ran Àwọn Èèyàn Lọ́wọ́

Àwọn nǹkan wo ni Jèhófà ṣe tó fi hàn pé òun lẹni tó lawọ́ jù lọ?

Tá a bá tiẹ̀ ń fún àwọn èèyàn ní nǹkan, àwọn ìwà wo ló yẹ ká yẹra fún kínú Ọlọ́run lè máa dùn sí wa?

Mt 6:1, 2; 2Kọ 9:7; 1Pe 4:9

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:

    • Jẹ 4:3-7; 1Jo 3:11, 12—Kí nìdí tí Ọlọ́run ò fi tẹ́wọ́ gba ẹbọ tí Kéènì rú?

    • Iṣe 5:1-11—Torí pé Ananáyà àti Sàfírà ò ní èrò tó tọ́ nípa ẹ̀bùn tí wọ́n mú wá, tí wọ́n sì parọ́, Jèhófà jẹ́ kí wọ́n jìyà ohun tí wọ́n ṣe

Kí ló máa jẹ́ kínú Ọlọ́run dùn sí wa tá a bá ń fún àwọn èèyàn ní nǹkan?

Mt 6:3, 4; Ro 12:8; 2Kọ 9:7; Heb 13:16

Tún wo Iṣe 20:35

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:

    • Lk 21:1-4—Ohun tí opó aláìní kan fi sílẹ̀ kéré gan-an, síbẹ̀ Jésù gbóríyìn fún un torí pé tọkàntọkàn ló fi mú un wá

Báwo làwọn Kristẹni ọgọ́rùn-ún ọdún kìíní ṣe ń ran ara wọn lọ́wọ́?

Iṣe 11:29, 30; Ro 15:25-27; 1Kọ 16:1-3; 2Kọ 9:5, 7

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:

    • Iṣe 4:34, 35—Àwọn ará nínú ìjọ Kristẹni fi tinútinú yọ̀ǹda àwọn nǹkan tí wọ́n ní, àwọn àpọ́sítélì sì pín in fáwọn aláìní

    • 2Kọ 8:1, 4, 6, 14—Ìjọ Kristẹni ṣètò bí wọ́n ṣe máa ran àwọn ará tó jẹ́ aláìní lọ́wọ́

Àwọn nǹkan pàtàkì wo ló yẹ káwa Kristẹni máa ṣe fáwọn tó wà nínú ìdílé wa àtàwọn tá a jọ ń sin Jèhófà?

Kí ni Bíbélì sọ pé ó yẹ ká máa ṣe fáwọn aláìní?

Báwo la ṣe mọ̀ pé ohun tó dáa jù lọ tá a lè ṣe fáwọn èèyàn ni pé ká ràn wọ́n lọ́wọ́ kí wọ́n lè mọ Jèhófà?

Mt 5:3, 6; Jo 6:26, 27; 1Kọ 9:23

Tún wo Owe 2:1-5; 3:13; Onw 7:12; Mt 11:4, 5; 24:14

  • Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:

    • Lk 10:39-42—Jésù jẹ́ kí Màtá mọ̀ pé ohun tó máa mú ká lájọṣe tó dáa pẹ̀lú Jèhófà ló yẹ kó ṣe pàtàkì jù sí wa