Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà
Owe 3:5, 21-26; Ais 26:3, 4; Jer 17:7, 8
Tún wo Sm 34:8; 40:4, 5; Owe 20:22; Ais 30:15
Àpẹẹrẹ inú Bíbélì:
1Kr 5:18-20, 22—Torí pé àwọn ọmọ Ísírẹ́lì gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà, wọ́n ṣẹ́gun àwọn ọ̀tá wọn
2Kr 14:9-13—Nígbà táwọn ọ̀tá tó lágbára dojú kọ Ọba Ásà, ó gbàdúrà, ó sì gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà