Saturday
“Ẹ máa kéde ìhìn rere ìgbàlà rẹ̀ láti ọjọ́ dé ọjọ́”—Sáàmù 96:2
Àárọ̀
-
9:20 Fídíò Orin
-
9:30 Orin 53 àti Àdúrà
-
9:40 “Mo Gbọ́dọ̀ . . . Kéde Ìhìn Rere Ìjọba Ọlọ́run” (Lúùkù 4:43)
-
9:50 FÍDÍÒ ÌTÀN BÍBÉLÌ:
Ìhìn Rere Látọ̀dọ̀ Jésù: Abala 1
Ìmọ́lẹ̀ Tòótọ́ fún Aráyé—Apá Kejì (Mátíù 2:1-23; Lúùkù 2:1-38, 41-52; Jòhánù 1:9)
-
10:25 Orin 69 àti Ìfilọ̀
-
10:35 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: Àsọtẹ́lẹ̀ Nípa Mèsáyà Ṣẹ!
-
• Ìránṣẹ́ kan wá ṣáájú rẹ̀ (Málákì 3:1; 4:5; Mátíù 11:10-14)
-
• Wúńdíá ló bí i (Àìsáyà 7:14; Mátíù 1:18, 22, 23)
-
• Wọ́n bí i sí Bẹ́tílẹ́hẹ́mù (Míkà 5:2; Lúùkù 2:4-7)
-
• Ohunkóhun ò ṣe é ní kékeré (Hósíà 11:1; Mátíù 2:13-15)
-
• Wọ́n pè é ní ará Násárẹ́tì (Àìsáyà 11:1, 2; Mátíù 2:23)
-
• Ó dé ní Àkókò tí Bíbélì sọ (Dáníẹ́lì 9:25; Lúùkù 3:1, 2, 21, 22)
-
-
11:40 ÌRÌBỌMI: Máa “Ṣègbọràn sí Ìhìn Rere” (2 Kọ́ríńtì 9:13; 1 Tímótì 4:12-16; Hébérù 13:17)
-
12:10 Orin 24 àti Àkókò Ìsinmi
Ọ̀sán
-
1:35 Fídíò Orin
-
1:45 Orin 83
-
1:50 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: Máa Fi Ìròyìn Rere Paná Ìròyìn Burúkú
-
• Òfófó (Àìsáyà 52:7)
-
• Ẹ̀rí Ọkàn Tó Ń Dani Láàmú (1 Jòhánù 1:7, 9)
-
• Àwọn Nǹkan Tó Ń Ṣẹlẹ̀ Láyé (Mátíù 24:14)
-
• Ìrẹ̀wẹ̀sì (Mátíù 11:28-30)
-
-
2:35 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: “Ara Mi Wà Lọ́nà Láti Kéde Ìhìn Rere”
-
• Kì í Ṣe Iṣẹ́ Àwọn Àpọ́sítẹ́lì Nìkan (Róòmù 1:15; 1 Tẹsalóníkà 1:8)
-
• Ara Ìjọsìn Wa Ni (Róòmù 1:9)
-
• Rí I Pé O Ní Àwọn Nǹkan Tó Yẹ (Éfésù 6:15)
-
-
3:15 FÍDÍÒ: “Bí Ìhìn Rere Náà Ṣe Ń So Èso, Tó sì Ń Gbilẹ̀ ní Gbogbo Ayé” (Kólósè 1:6)
-
3:40 Orin 35 àti Ìfilọ̀
-
3:50 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: Máa Wàásù Ìhìn Rere
-
• Níbikíbi Tó O Bá Wà (2 Tímótì 4:5)
-
• Níbikíbi Tí Ẹ̀mí Ọlọ́run Bá Darí Ẹ Sí (Ìṣe 16:6-10)
-
-
4:15 Kí Lo Máa Ṣe “Nítorí Ìhìn Rere”? (1 Kọ́ríńtì 9:23; Àìsáyà 6:8)
-
4:50 Orin 21 àti Àdúrà Ìparí