Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ 2010
Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ 2010
Ó ń tọ́ka sí Ilé Ìṣọ́ tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde
ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
Àárín Àwọn Èèyàn Ọlọ́run Lo Ti Lè Rí Ààbò, 6/15
A Batisí Wọn ní Orúkọ Baba, Ọmọ àti Ẹ̀mí Mímọ́, 3/15
Agbo Kan, Olùṣọ́ Àgùntàn Kan, 3/15
Aṣáájú Wa Lóde Òní, 9/15
Àwa Yóò Máa Rìn Nínú Ìwà Títọ́ Wa! 11/15
“Àwọn Olódodo Yóò Máa Tàn Yòò Bí Oòrùn,” 3/15
Bá A Ṣe Lè Rí Ìtura Nínú Àwọn Nǹkan Tẹ̀mí, 6/15
Bí Ìràpadà Ṣe Lè Gbà Wá Là, 8/15
Bí Jésù Ṣe Gbé Òdodo Ọlọ́run Lárugẹ, 8/15
Ẹ Jẹ́ Onítara fún Ìjọsìn Tòótọ́, 12/15
Ẹ Káàbọ̀ sí Ọ̀nà Ìgbésí Ayé Tó Dára Jù Lọ! 2/15
Ẹ Máa Gbé Ìjọ Ró, 6/15
Ẹ Máa Wá “Òdodo Rẹ̀” Lákọ̀ọ́kọ́, 10/15
Ẹ Má Ṣe Kó Ẹ̀dùn-Ọkàn Bá Ẹ̀mí Mímọ́ Jèhófà, 5/15
“Ẹ̀mí àti Ìyàwó Ń Bá A Nìṣó Ní Sísọ Pé: ‘Máa Bọ̀!’” 2/15
‘Ẹ̀mí Ń Wá Inú Àwọn Ohun Ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run,’ 7/15
Ẹ̀yin Arákùnrin, Ẹ Fúnrúgbìn Nípa Tẹ̀mí, Kẹ́ Ẹ Sì Máa Wá Àǹfààní, 5/15
Ẹ̀yin Obìnrin, Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Kẹ́ Ẹ Máa Tẹrí Ba fún Ipò Orí? 5/15
Ẹ̀yin Ọ̀dọ́, Ẹ Jẹ́ Kí Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run Máa Darí Yín, 11/15
Ẹ̀yin Ọ̀dọ́, Ẹ Má Ṣe Fàyè Gba Ẹ̀mí Ṣohun-Tẹ́gbẹ́-Ń-Ṣe, 11/15
Ẹ̀yin Ọ̀dọ́, Ẹ Mú Kí Ìfẹ́ Yín Láti Sin Jèhófà Jinlẹ̀ Sí I, 4/15
Ẹ̀yin Ọ̀dọ́, Kí Lẹ Máa Fi Ìgbésí Ayé Yín Ṣe? 11/15
Ẹ̀yin Ọkùnrin, Ṣé Ẹ̀ Ń Tẹrí Ba fún Ipò Orí Kristi? 5/15
Fi Hàn Pé Ojúlówó Ọmọlẹ́yìn Kristi Ni Ẹ́, 1/15
Inú Rere Àìlẹ́tọ̀ọ́sí Ni fún Wa Láti Jẹ́ Ti Jèhófà, 1/15
Ipa Tí Ẹ̀mí Mímọ́ Ń Kó Nínú Bí Ète Jèhófà Ṣe Ń Ní Ìmúṣẹ, 4/15
“Irú Ènìyàn Wo Ni Ó Yẹ Kí Ẹ Jẹ́!” 7/15
“Ìsinsìnyí Gan-An Ni Àkókò Ìtẹ́wọ́gbà,” 12/15
Ìṣàkóso Jèhófà Ló Dára Jù Lọ! 1/15
Ìṣàkóso Sátánì Máa Forí Ṣánpọ́n, 1/15
Iṣẹ́ Ìsìn! 5/15
Ìṣọ̀kan Àwa Kristẹni Ń Fi Ògo fún Ọlọ́run, 9/15
Ìṣọ̀kan La Fi Ń Dá Ìsìn Tòótọ́ Mọ̀, 9/15
Jèhófà Ni Olúwa Ọba Aláṣẹ Wa! 11/15
Jẹ́ Kí “Òfin Inú-Rere-Onífẹ̀ẹ́” Máa Fi Ìṣọ́ Ṣọ́ Ahọ́n Rẹ, 8/15
Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Kó O Ya Ara Rẹ Sí Mímọ́ fún Jèhófà? 1/15
Kórè Ìbùkún Yanturu Nípasẹ̀ Ọba Tí Ọlọ́run Ń Fi Ẹ̀mí Rẹ̀ Darí! 12/15
Kọrin sí Jèhófà! 12/15
Máa Fi Taratara Wá Ìbùkún Jèhófà, 9/15
Máa Kó Ipa Tó Jọjú Nínú Ìkórè Tẹ̀mí, 7/15
Máa Lo “Idà Ẹ̀mí” Lọ́nà Tó Jáfáfá, 2/15
Máa Rìn Nípa Ẹ̀mí Kó O sì Mú Ẹ̀jẹ́ Ìyàsímímọ́ Rẹ Ṣẹ, 3/15
‘Máa Sọ Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run Láìṣojo,’ 2/15
Máa Ṣàkóso Ìbínú Rẹ Kó O Lè “Máa Fi Ire Ṣẹ́gun Ibi,” 6/15
Má Ṣe Máa Wo Àwọn Ohun Tí Kò Ní Láárí! 4/15
Ǹjẹ́ O Máa Ń Mú Ipò Iwájú Nínú Bíbọlá fún Àwọn Tá a Jọ Jẹ́ Onígbàgbọ́? 10/15
Ohun Tí Ọjọ́ Jèhófà Máa Ṣí Payá, 7/15
“Ọ̀kan Ni Aṣáájú Yín, Kristi,” 9/15
Ọ̀rọ̀ Tútù Máa Ń Mú Kí Àjọṣe Wa Pẹ̀lú Àwọn Míì Sunwọ̀n Sí I, 6/15
Ṣé O Máa Ń Mú Kí Àwọn Ìpàdé Ìjọ Gbéni Ró? 10/15
Ṣé Ò Ń Tọ Kristi Lẹ́yìn Nígbà Gbogbo? 4/15
Ta Ló Lè Dá Àwọn Tó Ń Kígbe fún Ìrànlọ́wọ́ Nídè? 8/15
“Ta Ni Ó Ti Wá Mọ Èrò Inú Jèhófà?” 10/15
ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ
Ayẹyẹ Ìkẹ́kọ̀ọ́yege Ilé Ẹ̀kọ́ Gílíádì, 2/1, 8/1
Bulgaria, 9/15
Èèyàn Kì Í Dàgbà Jù Láti Sin Ọlọ́run (Sípéènì), 12/15
Erékùṣù Jíjìnnà Réré ní Àríwá Ọsirélíà, 5/1
Èrò Wọn Nípa Àwọn Ẹlẹ́sìn Ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ Tó Ń Jọ́sìn Pa Pọ̀, 6/1
Grenada, 9/1
Gbogbo Èèyàn La Pè (Bẹ́tẹ́lì), 8/15
Gbọ̀ngàn Ìjọba, 5/1
Haiti, 12/1
Ìpàdé Ọdọọdún, 6/15
Ìrántí Ikú Kristi, 3/1
Iṣẹ́ Ìwàásù àti Ìkọ́nilẹ́kọ̀ọ́ Nílẹ̀ Áfíríkà, 3/1
Ìwé Táá Jẹ́ Káwọn Ọ̀dọ́ Rántí Ẹlẹ́dàá Wọn (Àwọn Ọ̀dọ́ Béèrè Pé, Apá Kejì), 2/15
‘Ó Jẹ́ Kí Ọ̀rọ̀ Mi Wọni Lọ́kàn (ìwé kékeré Nations), 10/15
‘Ọrẹ Ẹbọ fún Jèhófà’ (àwọn ọrẹ), 11/15
Papua New Guinea, 3/1
South Africa, 6/1
Ṣé Wọ́n Máa Ń Fi Iṣẹ́ Ìyanu Ṣèwòsàn? 10/1
Wíwà Lójúfò (Finland), 7/15
BÍBÉLÌ
Ìdí Tí Mátíù Fi Sọ Pé Jeremáyà Ló Sọ Ọ̀rọ̀ Kan Tó Wà Nínú Ìwé Sekaráyà, 12/1
Ìdí Tí O Fi Lè Gbẹ́kẹ̀ Lé Àwọn Ìwé Ìhìn Rere, 3/1
Ìsíkíẹ́lì 18:20 àti Ẹ́kísódù 20:5 kò ta kora, 3/15
Ǹjẹ́ Ó Sọ Àsọtẹ́lẹ̀ Nípa Orílẹ̀-Èdè Ísírẹ́lì Òde Òní? 11/1
Ǹjẹ́ Ó Sọ Gbogbo Òtítọ́ Nípa Jésù fún Wa? 4/1
Òǹtẹ̀wé Ìjímìjí Kan Gbé E Lárugẹ, 7/1
Ó Ń Yí Ìgbésí Ayé Èèyàn Pa Dà, 2/1, 5/1, 8/1, 11/1
Ọ̀nà Méje Téèyàn Lè Gbà Jàǹfààní Látinú Bíbélì Kíkà, 7/1
Ṣé Ó Ní Ìmísí Ọlọ́run? 3/1
ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI
Àdúrà, 10/1
Adúróṣinṣin Nígbà Ìdánwò (Pétérù), 1/1
Àna, 2/1
Àwíjàre, 10/15
Àwọn Ọ̀nà Téèyàn Lè Gbà Ní Ìtẹ́lọ́rùn, 11/1
Àwọn Tí Ọkọ Tàbí Aya Wọn Kú, 5/1
Bá A Ṣe Lè Tọ́ Ọmọ Kan Di Ẹni Tó Dáńgájíá, 5/1
Bá Ò Ṣe Ní Pàdánù Ojúure Ọlọ́run Bí Ìyípadà Bá Tiẹ̀ Dé Bá Wa, 3/15
Bá Ọmọ Rẹ Sọ̀rọ̀ Nípa Ìbálòpọ̀, 11/1
Bó O Ṣe Lè Fara Dà Á bí Ọkọ Tàbí Aya Rẹ Bá Já Ẹ Jù Sílẹ̀, 6/15
Borí Èrò Òdì, 10/1
Bọ̀wọ̀ fún Àwọn Àgbàlagbà, 5/15
Dúró Lórí Ohun Tó O Gbà Gbọ́! (Jeremáyà), 5/1
‘Ẹ Jẹ́ Pípé bí Baba Yín Ọ̀run Ti Jẹ́ Pípé,’ 11/15
Ẹ̀kọ́ Nípa Àánú Ọlọ́run (Jónà), 3/1
“Ẹ̀tọ́ Àwọn Ọmọdé Láti Mọ Ọlọ́run,” 2/15
Ìgbatẹnirò fún Àwọn Òbí Tó Ń Dá Tọ́mọ, 12/1
Jẹ́ Kí Ìgbé Ayé Rẹ Ojoojúmọ́Máa Fi Ògo fún Ọlọ́run, 1/15
Jẹ́ Olóòótọ́ ní Gbogbo Ìgbà, 3/1
Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Kó O Máa Dé Lásìkò? 8/15
Kí Ni Ọmọ Rẹ Máa Sọ? 12/15
Kọ́ Àwọn Ọmọ Láti Nífẹ̀ẹ́ sí Ìwé Kíkà àti Ìkẹ́kọ̀ọ́, 7/15
Máa Dènà Ìpolongo Èké Sátánì, 2/15
‘Máa Fi Ara Rẹ fún Kíkọ́ni,’ 7/15
“Má Fòyà. Èmi Fúnra Mi Yóò Ràn Ọ́ Lọ́wọ́,” 7/15
Máa Lo Agbára Ìwòye, 5/15
Má Ṣe Jẹ́ Kí Èrò Àwọn Èèyàn Máa Darí Rẹ, 8/15
Ní ‘Ọkàn-àyà Tó Mọ́,’ 3/15
Ó Kọ́ Ìdáríjì Lọ́dọ̀ Ọ̀gá Rẹ̀ (Pétérù), 4/1
Ọdún Àkọ́kọ́ Ìgbéyàwó, 8/1
Ọkùnrin Onírẹ̀lẹ̀ àti Onígboyà (Jónà), 1/1
Ọ̀ràn Gbígbé Pa Pọ̀, 2/15
Ran Àwọn Ọ̀dọ́ Lọ́wọ́ Kí Wọ́n Lè Mọ Ètò Jèhófà Dunjú, 10/15
Ran Àwọn Ọmọ Lọ́wọ́ Láti Kojú Àwọn Ìṣòro, 1/15
Rí Àwọn Ọ̀rẹ́ Tó Jẹ́ Adúróṣinṣin, 7/1
Ṣé Ìwà Àìṣòótọ́ Ni? 6/1
Ṣé Ó Yẹ Kó O Máa Pa Sábáàtì Mọ́? 2/1
Ṣèrànwọ́ fún Ọ̀rẹ́ Tó Ń Ṣàìsàn, 7/1
“Títí Ikú Yóò Fi Yà Wá,” 3/1
Títọ́jú Ìbátan Tó Ń Ṣàìsàn, 5/15
Títún Ìrìbọmi Ṣe, 2/15
Tu Àwọn Tó Ń Ṣọ̀fọ̀ Nínú, 11/1
Wà ní “Àlàáfíà” àti Láìséwu, 4/15
ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ
Àdánwò Mú Ká Túbọ̀ Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà (A. Dello Stritto), 4/15
‘Àwọn Ohun Tó Ṣe Ti Bá A Lọ ní Tààràtà’ (T. Jaracz), 11/15
Bí Òtítọ́ Bíbélì Ṣe Lágbára Tó (V. Fraese), 12/15
Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà (E. Schmidt), 9/1
Mo Sìn Lásìkò Ìmúgbòòrò (H. Harris), 9/15
Ọlọ́run Jẹ́ “Olùṣe Àwọn Ohun Ńlá” (M. Raj), 12/1
Ọwọ́ Mi Dí Nínú Ètò Jèhófà (V. Zubko), 10/15
JÈHÓFÀ
Fẹ́ Kó O Wà ní “Àlàáfíà” àti Láìséwu, 4/15
Fún Wa Lómìnira Láti Ṣe Ohun Tó Wù Wá, 9/1
“Gbé Ọmọkùnrin Rẹ” (a jí ọmọkùnrin kan dìde), 8/1
Ìdúróṣinṣin, 6/1
‘Ìjọba Rẹ Yóò Fẹsẹ̀ Múlẹ̀’ (Dáfídì), 4/1
Kì Í Ṣe Ojúsàájú, 9/1
Kí Nìdí Tó Fi Fẹ́ Fún Aráyé Ní Ìyè Àìnípẹ̀kun? 1/1
Kọjú Ìjà sí Àwọn Ọmọ Kénáánì, 1/1
Mọ Ọkàn-Àyà, 12/1
Ń Gbọ́ Igbe Àwọn Ẹni Rírẹlẹ̀, 11/15
Nígbà Tí ‘Ọkàn Tí Ó Ní Ìròbìnújẹ́ Tí Ó sì Wó Palẹ̀’ Bá Tọrọ Ìdáríjì, 5/1
Ǹjẹ́ Gbogbo Èèyàn Ló Láǹfààní Kan Náà Láti Mọ? 8/1
Ǹjẹ́ O Kà Á sí Bàbá Rẹ? 2/15
Ǹjẹ́ Ó Lè Kẹ́dùn? 2/1
Ǹjẹ́ O Mọ Orúkọ Ọlọ́run? 7/1
Ǹjẹ́ Ó Ní Ìbẹ̀rẹ̀? 7/1
Ń Mú Ìlérí Ṣẹ, 1/1
‘Ń Wo Ọkàn-Àyà,’ 3/1
“Olùgbọ́ Àdúrà,” 10/1
Orúkọ Nínú Tẹ́ńpìlì Íjíbítì, 5/1
Rere Ló Ń Wò, 7/1
Ṣé Ò Ń Jẹ́ Kí Jèhófà Bi Ẹ́ Ní Ìbéèrè, 4/15
Ṣé Ọlọ́run Ti Pa Wá Tì? 5/1
“Yóò Jẹ́ Kí O Rí Òun” (1Kr 28:9), 11/1
JÉSÙ KRISTI
Àwọn Amòye Tó Wá Kí I, 12/1
Àwọn Tó Kọ̀wé Nípa Jésù, 6/1
Bí A Ṣe Lè Tẹ̀ Lé E, 5/1
Dárí Ẹ̀ṣẹ̀ Ji Obìnrin Kan, 8/15
Ìdí Tá A Fi Pè É Ní Kristi, 4/1
Ìdí Tí Kò Fi Kánjú, 8/1
Ìdí Tí Wọ́n Fi Kọ̀ Ọ́, 12/1
Káfíńtà, 8/1
Kẹ́kọ̀ọ́ Láti Jẹ́ Onígbọràn, 4/1
Kò Lọ́wọ́ Nínú Ìṣèlú, 7/1
Kọ́ni Nípa Àwọn Áńgẹ́lì, 11/1
Kọ́ni Nípa Bí A Ṣe Lè Láyọ̀, 8/1
Kọ́ni Nípa Ìjọsìn Tòótọ́, 2/1
Ǹjẹ́ Ó Bá Àwọn Àpọ́sítélì Tan? 9/1
Ǹjẹ́ Ó Bá Jòhánù Oníbatisí Tan? 9/1
Ó Gbé Ayé Rí, 4/1
Ọkùnrin Tó Ṣe Ohun Tó Ta Yọ Fáráyé, 4/1
Ṣé Irọ́ Ni àbí Òótọ́? 4/1
Ṣé Òun Ni Máíkẹ́lì Olú Áńgẹ́lì? 4/1
Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN
Aáwọ̀ Tó Wà Láàárín Àwọn Júù Àtàwọn Ará Samáríà, 10/1
Adẹ́tẹ̀ Rí Ìwòsàn Gbà (Náámánì), 11/1
Agbọ́tí Ọba, 7/1
A Kò Fìyà Jẹ Áárónì Nítorí Pé Ó Ṣe Ère Ọmọ Màlúù, 5/15
Àkọ́bí Tó Jẹ́ Ọkùnrin, 5/1
Àṣírí Tí O Lè Sọ fún Ẹlòmíì, 12/1
Àwọn Agbèjà Ìgbàgbọ́, 6/1
Àwọn Akóló Ìkó-Ìwé-Mímọ́-Sí, 5/1
“Àwọn Àpá Àmì Ti Ẹrú Jésù” (Ga 6:17), 11/1
“Àwọn Ibi Gíga,” 8/1
“Àwọn Ọkùnrin Ọlọ́bẹ Aṣóró” (Iṣe 21:38), 3/1
Àwọn Wo Ló Ń Gbé ní Ọ̀run? 12/1
Básámù Gílíádì, 6/1
Ẹ̀kọ́ Ìsìn Calvin, 9/1
Ẹ̀mí Mímọ́, 10/1
Ẹnubodè Ìlú, 6/1
Ẹran Tí Wọ́n Fi Rúbọ Sáwọn Òrìṣà, 10/1
Ẹ̀ṣẹ̀, 6/1
Fífi Èdè Fọ̀, 10/1
Háránì Ìlú Àtijọ́ Tó Kún fún Ìgbòkègbodò, 5/15
Ibo Ni Kéènì Ti Rí Ìyàwó Rẹ̀? 9/1
Ibo Ni Párádísè Tí Bíbélì Sọ Máa Wà? 12/1
Ìdí Táwọn Èèyàn Fi Ń Hùwà Ibi, 9/1
Ìjọba Tó Máa Yí Ìgbésí Ayé Àwọn Èèyàn Pa Dà, 10/1
Ilé Tí Wọ́n Ń Gbé (àwọn Kristẹni àkọ́kọ́bẹ̀rẹ̀), 1/1
Ìrìn Àjò Ayé Àtijọ́ Tó Kọjá Òkun Mẹditaréníà, 3/1
Ìrìn Àjò sí Apá Ibi Jíjìnnà Jù Lọ ní Ilẹ̀ Ayé, 11/1
Irú Ọtí Tí Wọ́n Máa Ń Ṣe Nígbà Tí Wọ́n Ń Kọ Bíbélì, 2/1
“Ìtọ́wọ̀ọ́rìn Aláyọ̀ Ìṣẹ́gun” (2Kọ 2:14-16), 8/1
Jíjẹ́wọ́ Ẹ̀ṣẹ̀, 9/1
Máàkù ‘Wúlò fún Iṣẹ́ Ìránṣẹ́,’ 3/15
Mẹ́talọ́kan, 2/1
Ǹjẹ́ Àwọn Èèyàn ní Àkókò Tí Wọ́n Ń Kọ Bíbélì Pẹ́ Láyé Gan-an? 12/1
Ǹjẹ́ Oúnjẹ àti Àlùmọ́ọ́nì Inú Ilẹ̀ Máa Tó? 3/1
Ó Gbàdúrà Àtọkànwá sí Ọlọ́run (Hánà), 7/1
Ojú Tí Àwọn Kristẹni Ọ̀rúndún Kìíní Fi Wo Òrìṣà Àwọn Ará Róòmù, 5/15
Ojú Tí Ọlọ́run Fi Ń Wo Ọtí Mímu, 1/1
Ó “Ń Bá A Lọ Ní Dídàgbà Lọ́dọ̀ Jèhófà” (Sámúẹ́lì), 10/1
“Òṣìṣẹ́ ní Ilé” (Tit 2:5), 2/1
Ó Ṣòro Láti Tukọ̀ Nígbà Ayé Pọ́ọ̀lù, 2/1
‘Ọjọ́ Èèyàn Yóò Jẹ́ Ọgọ́fà Ọdún’ (Jẹ 6:3), 12/15
Ọ̀nà Tí Pọ́ọ̀lù Gbà Nígbà Tó Rìnrìn Àjò (Ọ̀nà Ápíà), 1/1
Rèbékà, 2/1
Sínágọ́gù, 4/1
Ṣé Àwọn Èèrà Máa Ń Pèsè Oúnjẹ Sílẹ̀ Nígbà Ẹ̀ẹ̀rùn? 7/1
Ṣé Àwọn Ìràwọ̀ Ń Darí Ìgbésí Ayé Rẹ? 6/1
Ṣé Ayé Máa Pa Rẹ́? 1/1
Ṣé Gbogbo Èèyàn Rere Ló Ń Lọ sí Ọ̀run? 2/1
Ṣé Ibi Ààbò fún Àwọn Ọ̀daràn Ni Ìlú Ààbò Jẹ́? 11/1
Ṣé Òkú Lè Ran Alààyè Lọ́wọ́? 1/1
Ṣé Òpin Ti Sún Mọ́lé? 8/1
Ṣé Ó Yẹ Kí N Dara Pọ̀ Mọ́ Ẹ̀sìn Kan? 11/1
Ṣọ́ra fún Ẹ̀tàn, 9/1
‘Wáìnì Tuntun, Ògbólógbòó Àpò Awọ’ (Lu 5:37, 38), 3/1
Wàláà Ìkọ̀wé (Lu 1:63), 1/1
Wúrà Ófírì, 6/1