Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

KÍ NI BÍBÉLÌ FI KỌ́NI?

Kí Ni Ọlọ́run Ní Lọ́kàn Tó Fi Dá Ilẹ̀ Ayé? (Apá 2)

Orí kẹta ìwé Kí Ni Bíbélì Fi Kọ́ni Gan-an? ni ìwé ìkẹ́kọ̀ọ́ yìí dá lé.

Ṣàyẹ̀wò kó o lè mọ ẹni tó ń darí ayé yìí, tó sì wà nídìí gbogbo nǹkan burúkú tó ń ṣẹlẹ̀.