Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

KÍ NI BÍBÉLÌ FI KỌ́NI?

Kí Ni Ìjọba Ọlọ́run? (Apá 1)

Orí kẹjọ ìwé Kí Ni Bíbélì Fi Kọ́ni Gan-an? ni ìwé ìkẹ́kọ̀ọ́ yìí dá lé.

Wo ohun tó mú kí àwọn tó máa ṣàkóso lọ́run tóótun láti ṣe iṣẹ́ tí Ọlọ́run yàn fún wọn.