Dáfídì—Ó Gbẹ́kẹ̀ Lé Ọlọ́run
Dáfídì gbẹ́kẹ̀ lé Ọlọ́run. Kódà, nígbà tó dà bíi pé ìṣòro bò ó mọ́lẹ̀, kò fìgbà kan ṣíwọ́ pé òun ò sin Ọlọ́run mọ́. Wo bí Jèhófà ṣe bù kún Dáfídì torí pé ó jẹ́ adúróṣinṣin, kó o sì wo bó ṣe máa bù kún àwa náà tá a bá tẹ̀ lé àpẹẹrẹ rere Dáfídì.
O Tún Lè Wo
KÁÀDÌ ERÉ BÍBÉLÌ
Káàdì Eré Bíbélì Nípa Dáfídì
Ó ṣeé ṣe kó o mọ ìtàn Dáfídì àti Gòláyátì, àmọ́ ọ̀pọ̀ nǹkan ló ṣì yẹ kó o mọ̀ nípa Dáfídì.
ÀWỌN ÀWÒRÁN ÌTÀN BÍBÉLÌ
Dáfídì Jẹ́ Onígboyà
Kí ló mú kí Dáfídì gbà pá òun lè ṣẹ́gun Gòláyátì? Kí ló sì lè mú kó o nígboyà láti ṣe ohun tó tọ́?
ERÉ ALÁWÒRÁN
Dáfídì Nígboyà, Bí Ò Tiẹ̀ Ní Ju Ohun Ìjà Díẹ̀
Mú káàdì tí wọ́n ya àwọn èèyàn inú Bíbélì sí tó bára mu pẹ̀lú èyí tí wọ́n ya àwòrán àwọn nǹkan míì sí.