Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

April 17-23

Jeremáyà 25-28

April 17-23
  • Orin 137 àti Àdúrà

  • Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

  • Jẹ́ Onígboyà Bíi Jeremáyà”: (10 min.)

  • Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (8 min.)

    • Jer 27:2, 3—Kí ló lè fà á tí àwọn ońṣẹ́ láti oríṣiríṣi orílẹ̀-èdè fi wá sí Jerúsálẹ́mù, kí sì nìdí tí Jeremáyà fi ṣe ọ̀pá àjàgà fún wọn? (jr 27 ¶21)

    • Jer 28:11—Báwo ni Jeremáyà ṣe lo làákàyè nígbà tí Hananáyà ta kò ó, kí nìyẹn sì kọ́ wa? (jr 187-188 ¶11-12)

    • Kí ni Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí kọ́ ẹ nípa Jèhófà?

    • Àwọn ìṣúra tẹ̀mí wo lo tún rí látinú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí?

  • Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Jer 27:12-22

MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI