Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | JEREMÁYÀ 29-31

Jèhófà Sọ Àsọtẹ́lẹ̀ Nípa Májẹ̀mú Tuntun

Jèhófà Sọ Àsọtẹ́lẹ̀ Nípa Májẹ̀mú Tuntun

Jèhófà sọ pé òun máa fi májẹ̀mú tuntun rọ́pò májẹ̀mú Òfin, èyí tó máa ṣàǹfààní títí láé.

MÁJẸ̀MÚ ÒFIN

 

MÁJẸ̀MÚ TUNTUN

Jèhófà àti orílẹ̀-èdè Ísírẹ́lì nípa tara

ÀWỌN TÓ KÀN

Jèhófà àti Ísírẹ́lì tẹ̀mí

Mósè

ALÁRINÀ

Jésù Kristi

Ẹran ni wọ́n fi ń rúbọ

OHUN TÓ FÌDÍ RẸ̀ MÚLẸ̀

Jésù fi ara rẹ̀ rúbọ

Wàláà òkúta

IBI TÁ A KỌ Ọ́ SÍ

Ọkàn àwọn èèyàn