April 27–May 3
JẸ́NẸ́SÍSÌ 34-35
Orin 28 àti Àdúrà
Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (1 min.)
ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN
“Àkóbá Tí Ẹgbẹ́ Búburú Máa Ń Fà”: (10 min.)
Jẹ 34:1—Léraléra ni Dínà ń lọ sọ́dọ̀ àwọn ọmọbìnrin ilẹ̀ Kénáánì (w97 2/1 30 ¶4)
Jẹ 34:2—Ṣékémù fipá bá Dínà lò pọ̀ (lv 103 ¶14)
Jẹ 34:7, 25—Síméónì àti Léfì pa Ṣékémù àti gbogbo ọkùnrin to wà ní ìlú yẹn (w09 9/1 21 ¶1-2)
Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (10 min.)
Jẹ 35:8—Ta ni Dèbórà, kí la sì lè kọ́ lára rẹ̀? (it-1 600 ¶4)
Jẹ 35:22-26—Báwo la ṣe mọ̀ pé kò pọn dandan kí ìlà ìdílé tí Mèsáyà ti wá gba ọ̀dọ̀ àkọ́bí kọjá? (w17.12 14)
Àwọn ìṣúra tẹ̀mí wo lo tún rí nínú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí nípa Jèhófà, iṣẹ́ ìwàásù tàbí àwọn nǹkan míì?
Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Jẹ 34:1-19 (th ẹ̀kọ́ 5)
MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ
Ìpadàbẹ̀wò Kejì—Fídíò: (5 min.) Ìjíròrò. Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò náà, lẹ́yìn náà béèrè àwọn ìbéèrè yìí: Kí ni Ẹ̀bùn ṣe kí ọ̀rọ̀ rẹ̀ lè wọ onílé lọ́kàn? Báwo la ṣe lè fi ìwé Bíbélì Kọ́ Wa bẹ̀rẹ̀ ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì?
Ìpadàbẹ̀wò Kejì: (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Lo ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ tó wà lójú ìwé 1. (th ẹ̀kọ́ 13)
Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì: (5 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) fg ẹ̀kọ́ 4 ¶6-7 (th ẹ̀kọ́ 14)
MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI
“Ẹ Mú Àwọn Ọlọ́run Àjèjì Kúrò”: (15 min.) Ìjíròrò. Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò náà “Ẹ Dojú Ìjà Kọ Èṣù”.
Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) bh orí 18 ¶14-22
Ọ̀rọ̀ Ìparí (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)
Orin 143 àti Àdúrà