Ìtòlẹ́sẹẹsẹ Ìpàdé Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni ti Ọ̀sẹ̀ February 5-11, 2018
MÁTÍÙ 12-13
Orin 27 àti Àdúrà
Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)
ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN
“Àkàwé Àlìkámà àti Èpò”: (10 min.)
Mt 13:24-26—Ọkùnrin kan fún irúgbìn àtàtà sínú pápá rẹ̀, ọ̀tá rẹ̀ wá, ó sì fún àwọn èpò sí àárín pápá náà (w13 7/15 9-10 ¶2-3)
Mt 13:27-29—Àlìkámà àti èpò dàgbà pa pọ̀ títí di ìgbà ìkórè (w13 7/15 10 ¶4)
Mt 13:30—Nígbà ìkórè, àwọn olùkórè kọ́kọ́ kó èpò, wọ́n sì gbá àlìkámà jọ (w13 7/15 12 ¶10-12)
Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (8 min.)
Mt 12:20—Báwo la ṣe lè máa fi àánú hàn bíi ti Jésù? (“Òwú àtùpà” àlàyé ọ̀rọ̀ lórí Mt 12:20, nwtsty)
Mt 13:25—Ṣé òótọ́ ni pé láyé àtijọ́, ó ṣeé ṣe kí ẹnì kan fún èpò sínú pápá ẹlòmíì? (w16.10 32)
Kí ni Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí kọ́ ẹ nípa Jèhófà?
Àwọn ìṣúra tẹ̀mí wo lo tún rí látinú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí?
Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Mt 12:1-21
MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ
Nígbà Àkọ́kọ́—Fídíò: (4 min.) Ẹ wo fídíò náà, kẹ́ ẹ sì jíròrò rẹ̀.
Ìpadàbẹ̀wò àkọ́kọ́: (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Lo ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ.
Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì: (6 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) bh 21-23 ¶10-12
MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI
Ohun Tó Ń Fẹ́ Àbójútó Nínú Ìjọ: (5 min.)
“Àǹfààní Tá A Lè Rí Nínú Ìtumọ̀ Àwọn Àpèjúwe Ìjọba Ọlọ́run”: (10 min.) Ìjíròrò. Ẹ jíròrò bí àwọn àpèjúwe yìí ṣe lè ràn wá lọ́wọ́ lẹ́nu iṣẹ́ òjíṣẹ́ wa.
Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) lv àfikún Ọwọ́ Tó Yẹ Ká Fi Mú Ẹni Tí Wọ́n Bá Yọ Lẹ́gbẹ́
Àtúnyẹ̀wò àti Ohun Tá A Máa Kọ́ Lọ́sẹ̀ Tó Ń Bọ̀ (3 min.)
Orin 10 àti Àdúrà