February 18-24
RÓÒMÙ 7-8
Orin 27 àti Àdúrà
Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)
ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN
“Ṣé Ò Ń Fojú Sọ́nà Pẹ̀lú Ìháragàgà?”: (10 min.)
Ro 8:19—A máa tó ṣí “àwọn ọmọ Ọlọ́run” payá (w12 7/15 11 ¶17)
Ro 8:20—“A tẹ ìṣẹ̀dá lórí ba fún ìmúlẹ̀mófo . . . nítorí ìrètí” (w12 3/15 23 ¶11)
Ro 8:21—‘A óò dá ìṣẹ̀dá sílẹ̀ kúrò lọ́wọ́ ìsọdẹrú fún ìdíbàjẹ́’ (w12 3/15 23 ¶12)
Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (8 min.)
Ro 8:6—Kí ni ìyàtọ̀ tó wà láàárín “gbígbé èrò inú ka ẹran ara” àti “gbígbé èrò inú ka ẹ̀mí”? (w17.06 3)
Ro 8:26, 27—Báwo ni Jèhófà ṣe máa ń dáhùn “àwọn ìkérora tí a kò sọ jáde”? (w09 11/15 7 ¶20)
Kí ni Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí kọ́ ẹ nípa Jèhófà?
Àwọn ìṣúra tẹ̀mí wo lo tún rí látinú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí?
Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Ro 7:13-25 (th ẹ̀kọ́ 10)
MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ
Ìpadàbẹ̀wò Àkọ́kọ́—Fídíò: (5 min.) Ẹ wo fídíò náà, kẹ́ ẹ sì jíròrò rẹ̀.
Ìpadàbẹ̀wò Àkọ́kọ́: (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Lo ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ tó wà lójú ìwé 1. (th ẹ̀kọ́ 6)
Ìpadàbẹ̀wò Àkọ́kọ́: (5 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Lo ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ tó wà lójú ìwé 1, ṣe bíi pé ẹ wo fídíò Báwo La Ṣe Máa Ń Ṣe Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì? lẹ́yìn náà, kẹ́ ẹ jíròrò rẹ̀. (th ẹ̀kọ́ 9)
MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI
“Máa Fi Ìháragàgà Dúró Dè É Pẹ̀lú Ìfaradà”: (15 min.) Ìjíròrò. Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò A Gbọ́dọ̀ ‘Fi Ìfaradà Sáré’—Jẹ́ Kó Dá Ọ Lójú Pé Wàá Gba Èrè.
Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) bh orí 3 ¶1-6
Àtúnyẹ̀wò àti Ohun Tá A Máa Kọ́ Lọ́sẹ̀ Tó Ń Bọ̀ (3 min.)
Orin 124 àti Àdúrà