Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

February 18-​24

RÓÒMÙ 7-8

February 18-​24
  • Orin 27 àti Àdúrà

  • Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

  • Ṣé Ò Ń Fojú Sọ́nà Pẹ̀lú Ìháragàgà?”: (10 min.)

  • Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (8 min.)

    • Ro 8:6​—Kí ni ìyàtọ̀ tó wà láàárín “gbígbé èrò inú ka ẹran ara” àti “gbígbé èrò inú ka ẹ̀mí”? (w17.06 3)

    • Ro 8:26, 27​—Báwo ni Jèhófà ṣe máa ń dáhùn “àwọn ìkérora tí a kò sọ jáde”? (w09 11/15 7 ¶20)

    • Kí ni Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí kọ́ ẹ nípa Jèhófà?

    • Àwọn ìṣúra tẹ̀mí wo lo tún rí látinú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí?

  • Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Ro 7:13-25 (th ẹ̀kọ́ 10)

MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI