Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

February 5-11

SÁÀMÙ 1-4

February 5-11

Orin 150 àti Àdúrà | Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (1 min.)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

1. Fara Mọ́ Ìjọba Ọlọ́run

(10 min.)

[Jẹ́ kí àwọn ará wo FÍDÍÒ Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Sáàmù.]

Àwọn aláṣẹ ayé ti sọ ara wọn di ọ̀tá Ìjọba Ọlọ́run (Sm 2:2; w21.09 15 ¶8)

Jèhófà ń fún gbogbo èèyàn láǹfààní láti pinnu bóyá wọ́n máa fara mọ́ Ìjọba rẹ̀ (Sm 2:10-12)

BI ARA RẸ PÉ, ‘Ṣé mo ti pinnu pé mi ò ní dá sí ọ̀rọ̀ òṣèlú lọ́nàkọnà, kódà tíyẹn bá máa mú kí nǹkan nira fún mi?’—w16.04 24 ¶11.

2. Àwọn Ẹ̀kọ́ Iyebíye Míì

(10 min.)

  • Sm 1:4—Báwo làwọn èèyàn burúkú ṣe dà bí “ìyàngbò tí afẹ́fẹ́ ń gbá lọ”? (it-1 425)

  • Àwọn ẹ̀kọ́ iyebíye wo lo rí nínú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí tí wàá fẹ́ sọ?

3. Bíbélì Kíkà

TẸRA MỌ́ IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

4. Máa Bẹ̀rẹ̀ Ọ̀rọ̀ Ẹ Wẹ́rẹ́—Ohun Tí Fílípì Ṣe

(7 min.) Ìjíròrò. Jẹ́ kí àwọn ará wo FÍDÍÒ náà, kẹ́ ẹ sì jíròrò lmd ẹ̀kọ́ 2 kókó 1-2.

5. Máa Bẹ̀rẹ̀ Ọ̀rọ̀ Ẹ Wẹ́rẹ́—Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Fílípì

(8 min.) Ìjíròrò tó dá lórí lmd ẹ̀kọ́ 2 kókó 3-5 àti apá “Tún Wo.”

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

Orin 32

6. Ohun Tó Ń Fẹ́ Àbójútó Nínú Ìjọ

(15 min.)

7. Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ

Ọ̀rọ̀ Ìparí (3 min.) | Orin 61 àti Àdúrà