February 17-23
ÒWE 1
Orin 88 àti Àdúrà | Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (1 min.)
1. Ẹ̀yin Ọ̀dọ́—Ta Lẹ Máa Fetí Sí?
(10 min.)
[Jẹ́ kí àwọn ará wo FÍDÍÒ Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Òwe.]
Jẹ́ ọlọgbọ́n kó o sì máa fetí sí àwọn òbí ẹ (Owe 1:8; w17.11 29 ¶16-17; wo àwòrán)
Má ṣe fetí sí àwọn tó ń ṣe ohun tí kò dáa (Owe 1:10, 15; w05 2/15 19-20 ¶11-12)
2. Àwọn Ẹ̀kọ́ Iyebíye Míì
(10 min.)
-
Owe 1:22—Tí Bíbélì bá lo ọ̀rọ̀ náà “òmùgọ̀,” àwọn wo ló sábà máa ń tọ́ka sí? (it-1 846)
-
Àwọn ẹ̀kọ́ iyebíye wo lo rí nínú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí tí wàá fẹ́ sọ?
3. Bíbélì Kíkà
(4 min.) Owe 1:1-23 (th ẹ̀kọ́ 10)
4. Bá A Ṣe Lè Bẹ̀rẹ̀ Ọ̀rọ̀ Wa
(2 min.) ÌWÀÁSÙ NÍBI TÍ ÈRÒ PỌ̀ SÍ. Ẹni náà fẹ́ bá ẹ jiyàn. (lmd ẹ̀kọ́ 6 kókó 5)
5. Bá A Ṣe Lè Bẹ̀rẹ̀ Ọ̀rọ̀ Wa
(2 min.) ÌWÀÁSÙ NÍBI TÍ ÈRÒ PỌ̀ SÍ. Gba nọ́ńbà ẹni tó nífẹ̀ẹ́ sí ọ̀rọ̀ ẹ. (lmd ẹ̀kọ́ 1 kókó 5)
6. Pa Dà Lọ
(2 min.) ÌWÀÁSÙ ÀÌJẸ́-BÍ-ÀṢÀ. Ṣàlàyé bá a ṣe máa ń kọ́ àwọn èèyàn lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì, kó o sì fún ẹni náà ní káàdì ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì. (lmd ẹ̀kọ́ 9 kókó 5)
7. Sọ Àwọn Èèyàn Di Ọmọ Ẹ̀yìn
(5 min.) lff ẹ̀kọ́ 16 kókó 6. Akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì ẹ kan ń ṣiyèméjì pé bóyá làwọn iṣẹ́ ìyanu tí Jésù ṣe wáyé lóòótọ́. Fi àpilẹ̀kọ kan lápá “Ṣèwádìí” ṣàlàyé fún un. (th ẹ̀kọ́ 3)
Orin 89
8. Ohun Tó Ń Fẹ́ Àbójútó Nínú Ìjọ
(15 min.)
9. Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ
(30 min.) bt orí 22 ¶15-21