Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

August 14-20

NEHEMÁYÀ 8-9

August 14-20
  • Orin 110 àti Àdúrà

  • Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (1 min.)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

  • Ìdùnnú Jèhófà Ni Ibi Ààbò Yín”: (10 min.)

  • Àwọn Ẹ̀kọ́ Iyebíye Míì: (10 min.)

    • Ne 8:2, 8​—Tó bá jẹ́ pé àwọn ọmọ Ísírẹ́lì “lè lóye” Òfin Ọlọ́run tí wọ́n kà, kí nìdí táwọn ọmọ Léfì tún fi ṣàlàyé ẹ̀ fún wọn? (it-1 145 ¶2)

    • Àwọn ẹ̀kọ́ iyebíye wo lo tún rí nínú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí nípa Jèhófà, iṣẹ́ ìwàásù tàbí àwọn nǹkan míì?

  • Bíbélì Kíkà: (4 min.) Ne 8:1-12 (th ẹ̀kọ́ 10)

TẸRA MỌ́ IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI