Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

July 24-30

NEHEMÁYÀ 1-2

July 24-30
  • Orin 47 àti Àdúrà

  • Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (1 min.)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

  • Lójú Ẹsẹ̀, Mo Gbàdúrà”: (10 min.)

  • Àwọn Ẹ̀kọ́ Iyebíye Míì: (10 min.)

    • Ne 2:4​—Ṣé ìgbà àkọ́kọ́ rèé tí Nehemáyà máa gbàdúrà nípa ọ̀rọ̀ yìí, ẹ̀kọ́ wo la sì rí kọ́ nínú ohun tó ṣe? (w86 6/1 21)

    • Àwọn ẹ̀kọ́ iyebíye wo lo tún rí nínú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí nípa Jèhófà, iṣẹ́ ìwàásù tàbí àwọn nǹkan míì?

  • Bíbélì Kíkà: (4 min.) Ne 2:11-20 (th ẹ̀kọ́ 2)

TẸRA MỌ́ IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

  • Orin 44

  • Di Ọ̀rẹ́ Jèhófà​—Ṣé Jèhófà Máa Ń Dáhùn Àdúrà?: (15 min.) Ìjíròrò. Jẹ́ káwọn ará wo fídíò náà. Lẹ́yìn náà béèrè pé, Kí ni fídíò yìí kọ́ wa nípa àdúrà?

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) lff ẹ̀kọ́ 51

  • Ọ̀rọ̀ Ìparí (3 min.)

  • Orin 102 àti Àdúrà