ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | FÍLÍPÌ 1-4 “Ẹ Má Ṣe Máa Ṣàníyàn Nípa Ohunkóhun” TẸ̀ Ẹ̣́ “Ẹ Má Ṣe Máa Ṣàníyàn Nípa Ohunkóhun” 4:6, 7 Àdúrà ni oògùn àníyàn Tá a bá gbàdúrà, tá a sì ní ìgbàgbọ́, Jèhófà máa fún wa ní àlàáfíà “tó kọjá gbogbo òye” Lóòótọ́ ó lè jọ pé kò sí ọ̀nà àbáyọ sí àwọn ìṣòro wa, àmọ́ Jèhófà lè ràn wá lọ́wọ́ láti fara dà á. Ó tiẹ̀ lè ṣe kọjá ohun tá a rò pàápàá.—1Kọ 10:13 Pa Dà Èyí Tó Kàn Tẹ̀ ẹ́ Fi ránṣẹ́ Fi ránṣẹ́ “Ẹ Má Ṣe Máa Ṣàníyàn Nípa Ohunkóhun” ÌWÉ ÌPÀDÉ ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ ÀWA KRISTẸNI “Ẹ Má Ṣe Máa Ṣàníyàn Nípa Ohunkóhun” Yorùbá “Ẹ Má Ṣe Máa Ṣàníyàn Nípa Ohunkóhun” https://cms-imgp.jw-cdn.org/img/p/202019211/univ/art/202019211_univ_sqr_xl.jpg