March 28 sí April 3
JÓÒBÙ 11-15
Orin 111 àti Àdúrà
Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)
ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN
“Jóòbù Gbà Pé Àjíǹde Máa Wà”: (10 min.)
Job 14:1, 2
—Jóòbù ṣe àkópọ̀ bí ìgbésí ayé àwa èèyàn ṣe rí (w15 3/1 ojú ìwé 3; w10 5/1 ojú ìwé 5 ìpínrọ̀ 2; w08 3/1 ojú ìwé 3 ìpínrọ̀ 3) Job 14:13-15a
—Jóòbù mọ̀ pé Jèhófà kò ní gbàgbé òun (w15 8/1 ojú ìwé 5; w14 1/1 ojú ìwé 7 ìpínrọ̀ 4; w11 3/1 ojú ìwé 22 ìpínrọ̀ 2 sí 4) Job 14:15b
—Jèhófà mọyì àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ olóòótọ́ (w15 8/1 ojú ìwé 7 ìpínrọ̀ 3; w14 6/15 ojú ìwé 14 ìpínrọ̀ 12; w11 3/1 ojú ìwé 22 ìpínrọ̀ 3 sí 6)
Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (8 min.)
Job 12:12
—Kí nìdí tí àwọn Kristẹni tó jẹ́ àgbàlagbà fi lè ran àwọn ọ̀dọ́ lọ́wọ́? (g99 8/8 ojú ìwé 19, àpótí) Job 15:27
—Kí ni Élífásì ní lọ́kàn nígbà tó dọ́gbọ́n sọ fún Jóòbù pé ‘ọ̀rá ni ó fi bo ojú ara rẹ̀’? (it-1 ojú ìwé 802 ìpínrọ̀ 4) Ẹ̀kọ́ wo ni Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí kọ́ mi nípa Jèhófà?
Àwọn kókó wo látinú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí ni mo lè lò lóde ẹ̀rí?
Bíbélì Kíkà: Job 14:1-22 (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)
MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ
Nígbà Àkọ́kọ́: fg ẹ̀kọ́ 13 ìpínrọ̀ 1
—Sọ ohun tí wàá bá ẹni náà jíròrò nígbà tó o bá pa dà wá. (2 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Ìpadàbẹ̀wò:: fg ẹ̀kọ́ 13 ìpínrọ̀ 2
—Sọ ohun tí wàá bá ẹni náà jíròrò nígbà tó o bá tún pa dà wá. (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì: fg ẹ̀kọ́ 13 ìpínrọ̀ 3 àti 4 (6 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀))
MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI
Orin 134
Ohun tó ń fẹ́ àbójútó nínú ìjọ: (5 min.)
“Ìràpadà Mú Kí Àjíǹde Ṣeé Ṣe”: (10 min.) Ìjíròrò. Ní ìparí ìjíròrò yìí, jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò tá a wò ní Àpéjọ Àgbègbè “Ẹ Kọ́kọ́ Máa Wá Ìjọba Ọlọ́run!” ti ọdún 2014.
Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: ia orí 12 ìpínrọ̀ 1 sí 12 (30 min.)
Àtúnyẹ̀wò àti Ohun Tá A Máa Kọ́ Lọ́sẹ̀ Tó Ń Bọ̀ (3 min.)
Orin 33 àti Àdúrà