ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | RÓÒMÙ 15-16
Bẹ Jèhófà Pé Kó Fún Ẹ Ní Ìfaradà Kó sì Tù Ẹ́ Nínú
Ọ̀kan lára àwọn nǹkan tí Jèhófà máa ń lò láti pèsè ìtùnú àti ìfaradà fún wa ni Bíbélì Ọ̀rọ̀ rẹ̀. Báwo ni àpẹẹrẹ àwọn tó wà nínú Bíbélì yìí ṣe fún ẹ ní ìṣírí àti ìtùnú?
Nóà
Jósẹ́fù
Dáfídì