March 2-8
JẸ́NẸ́SÍSÌ 22-23
Orin 89 àti Àdúrà
Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (1 min.)
ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN
“Ọlọ́run Dán Ábúráhámù Wò”: (10 min.)
Jẹ 22:1, 2—Ọlọ́run sọ fún Ábúráhámù pé kó fi Ísákì ọmọ ẹ̀ tó nífẹ̀ẹ́ gidigidi rúbọ (w12 1/1 23 ¶4-6)
Jẹ 22:9-12—Jèhófà ò jẹ́ kí Ábúráhámù pa Ísákì
Jẹ 22:15-18—Jèhófà ṣèlérí pé òun máa bù kún Ábúráhámù torí pé ó jẹ́ onígbọràn (w12 10/15 23 ¶6)
Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (10 min.)
Jẹ 22:5—Kí ló mú kí Ábúráhámù sọ fáwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pé òun àti Ísákì máa pa dà wá bó tilẹ̀ jẹ́ pé ó mọ̀ pé òun máa tó fi Ísákì rúbọ? (w16.02 7 ¶13)
Jẹ 22:12—Báwo ni ẹsẹ Bíbélì yìí ṣe jẹ́ ká mọ̀ pé kì í ṣe gbogbo ìgbà ni Jèhófà máa ń lo agbára tó ní láti mọ ohun tó máa ṣẹlẹ̀ lọ́jọ́ iwájú? (it-1 853 ¶5-6)
Àwọn ìṣúra tẹ̀mí wo lo tún rí nínú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí nípa Jèhófà, iṣẹ́ ìwàásù tàbí àwọn nǹkan míì?
Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Jẹ 22:1-18 (th ẹ̀kọ́ 2)
MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ
Tẹra Mọ́ Kíkàwé àti Kíkọ́ni: (10 min.) Ìjíròrò. Ẹ wo fídíò Fi Ìdánilójú Sọ̀rọ̀, lẹ́yìn náà, ẹ jíròrò ẹ̀kọ́ 15 nínú ìwé pẹlẹbẹ Kíkọ́ni.
Àsọyé: (5 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) it-1 604 ¶5—Àkòrí: Kí Ló Mú Kí Ọlọ́run Ka Ábúráhámù sí Olódodo kí Jésù Tó San Ìràpadà? (th ẹ̀kọ́ 7)
MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI
Ìgbọràn Ń Dáàbò Bò Wá: (15 min.) Ẹ wo fídíò náà Ìpàdé Ọdọọdún 2017—Àwọn Àsọyé àti Ẹsẹ Ìwé Mímọ́ Ọdún 2018—Àyọlò.
Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) bh orí 16 ¶11-15 àti àfikún Ǹjẹ́ Ó Yẹ Ká Máa Ṣe Ọdún àti Àwọn Ayẹyẹ Kan?
Ọ̀rọ̀ Ìparí (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)
Orin 16 àti Àdúrà