Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Bí Ìgbàgbọ́ Ṣe Lè Jẹ́ Ká Nígboyà

Bí Ìgbàgbọ́ Ṣe Lè Jẹ́ Ká Nígboyà

Àwọn amí tó mú ìròyìn burúkú wá ò nígbàgbọ́ (Nọ 13:​31-33; 14:11)

Torí pé àwọn amí mẹ́wàá yẹn ò nígbàgbọ́, wọ́n kó ìrẹ̀wẹ̀sì bá àwọn tó kù (Nọ 14:​1-4)

Àwọn amí tó jẹ́ onígboyà fi hàn pé àwọn ní ìgbàgbọ́ tó lágbára (Nọ 14:​6-9; w06 10/1 17 ¶5-6)

Ṣáájú ìgbà yẹn, àwọn ọmọ Ísírẹ́lì ti fojú ara wọn rí bí Jèhófà ṣe gbà wọ́n là, tó sì jà fún wọn. Ó yẹ kí àwọn nǹkan tí wọ́n rí yẹn mú kí ìgbàgbọ́ wọn lágbára, kí wọ́n sì gbà pé Jèhófà máa ràn wọ́n lọ́wọ́ láti ṣẹ́gun àwọn ọmọ Kénáánì.