ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN
Bí Jèhófà Ṣe Ń Darí Àwọn Èèyàn Rẹ̀
Jèhófà ló máa ń pinnu ibi tó yẹ káwọn èèyàn rẹ̀ lọ àti ìgbà tó yẹ kí wọ́n gbéra (Nọ 9:17, 18; it-1 398 ¶3)
Ẹsẹ̀kẹsẹ̀ làwọn ọmọ Ísírẹ́lì gbọ́dọ̀ tẹ̀ lé ìtọ́ni Jèhófà (Nọ 9:21, 22; w11 4/15 4-5)
Àwọn èèyàn aláìpé ni Jèhófà máa ń lò láti fún àwọn èèyàn rẹ̀ ní ìtọ́ni (Nọ 10:5-8)
Tá a bá ń ṣègbọràn sáwọn tí Jèhófà ń lò láti darí wa, Jèhófà là ń ṣègbọràn sí.