ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN
Ìmọ̀ràn Onífẹ̀ẹ́ Tí Bàbá Kan Fún Ọmọ Ẹ̀
Sapá kó o lè mọ Jèhófà (1Kr 28:9; w05 2/15 19 ¶9)
Fi gbogbo ọkàn rẹ sin Jèhófà (1Kr 28:9; w12 4/15 16 ¶13)
Má bẹ̀rù, Jèhófà ni kó o gbẹ́kẹ̀ lé (1Kr 28:20; w17.09 32 ¶20-21)
Ọba Dáfídì tó ti darúgbó fún Sólómọ́nì ọmọ rẹ̀ tó jẹ́ ọ̀dọ́ tí ò sì nírìírí nímọ̀ràn kó tó bẹ̀rẹ̀ sí í kọ́ tẹ́ńpìlì tó jẹ́ iṣẹ́ tó ṣe pàtàkì. Kí nìdí tí ìmọ̀ràn tó fún un yìí fi wúlò fún gbogbo wa, pàápàá àwọn Kristẹni tó jẹ́ ọ̀dọ́?