Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

March 25-31

SÁÀMÙ 22

March 25-31

Orin 19 àti Àdúrà | Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (1 min.)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Àwọn ọmọ ogun ń ṣẹ́ kèké lórí ẹni tó máa mú aṣọ àwọ̀lékè Jésù

1. Bíbélì Sọ Tẹ́lẹ̀ Nípa Ohun Táá Ṣẹlẹ̀ Nígbà Ikú Jésù

(10 min.)

Ó máa dà bíi pé Ọlọ́run ti kọ Jésù sílẹ̀ (Sm 22:1; w11 8/15 15 ¶16)

Wọ́n á fi Jésù ṣe yẹ̀yẹ́, wọ́n á sì sọ̀rọ̀ àbùkù sí i (Sm 22:7, 8; w11 8/15 15 ¶13)

Wọ́n á ṣẹ́ kèké lórí aṣọ Jésù (Sm 22:18; w11 8/15 15 ¶14; wo àwòrán iwájú ìwé)

BI ARA RẸ PÉ, ‘Báwo ni Sáàmù 22 ṣe mú kó túbọ̀ dá mi lójú pé àwọn àsọtẹ́lẹ̀ tó kù nípa Mèsáyà, irú bí èyí tó wà nínú Míkà 4:4 máa ṣẹ láìkùnà?’

2. Àwọn Ẹ̀kọ́ Iyebíye Míì

(10 min.)

  • Sm 22:22—Àwọn ọ̀nà méjì wo la lè gbà ṣe bíi ti onísáàmù náà lónìí? (w06 11/1 29 ¶7; w03 9/1 20 ¶1)

  • Àwọn ẹ̀kọ́ iyebíye wo lo rí nínú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí tí wàá fẹ́ sọ?

3. Bíbélì Kíkà

TẸRA MỌ́ IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

4. Bá A Ṣe Lè Bẹ̀rẹ̀ Ọ̀rọ̀ Wa

(3 min.) ÌWÀÁSÙ ILÉ-DÉ-ILÉ. (lmd ẹ̀kọ́ 4 kókó 4)

5. Pa Dà Lọ

(4 min.) ÌWÀÁSÙ ÀÌJẸ́-BÍ-ÀṢÀ. Pa dà lọ sọ́dọ̀ ẹnì kan tó o pè, tó sì wá sí Ìrántí Ikú Kristi. (lmd ẹ̀kọ́ 4 kókó 3)

6. Àsọyé

(5 min.) w20.07 12-13 ¶14-17—Àkòrí: Bí Àwọn Àsọtẹ́lẹ̀ Bíbélì Ṣe Ń Jẹ́ Kí Ìgbàgbọ́ Wa Túbọ̀ Lágbára. (th ẹ̀kọ́ 20)

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

Orin 95

7. Ohun Tó Ń Fẹ́ Àbójútó Nínú Ìjọ

(15 min.)

8. Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ

Ọ̀rọ̀ Ìparí (3 min.) | Orin 53 àti Àdúrà