June 28–July 4
DIUTARÓNÓMÌ 9-10
Orin 49 àti Àdúrà
Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (1 min.)
ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN
“Kí Ni Jèhófà Ọlọ́run Rẹ Fẹ́ Kó O Ṣe?”: (10 min.)
Àwọn Ìṣúra Tẹ̀mí: (10 min.)
Di 9:1-3—Bó tiẹ̀ jẹ́ pé àwọn ọmọ Ánákì ‘tóbi, tí wọ́n sì ga,’ kí nìdí tí kò fi yẹ káwọn ọmọ Ísírẹ́lì bẹ̀rù wọn? (it-1 103)
Àwọn ìṣúra tẹ̀mí wo lo tún rí nínú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí nípa Jèhófà, iṣẹ́ ìwàásù tàbí àwọn nǹkan míì?
Bíbélì Kíkà: (4 min.) Di 10:1-22 (th ẹ̀kọ́ 10)
MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ
Nígbà Àkọ́kọ́: (3 min.) Bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ. Fún onílé ní ọ̀kan lára àwọn ìtẹ̀jáde tó wà nínú Àpótí Ìkọ́nilẹ́kọ̀ọ́. (th ẹ̀kọ́ 3)
Ìpadàbẹ̀wò: (4 min.) Bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ. Ṣe bíi pé ẹ wo fídíò Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Kó O Kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì? (àmọ́ ẹ má ṣe wò ó) (th ẹ̀kọ́ 9)
Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì: (5 min.) fg ẹ̀kọ́ 12 ¶4-5 (th ẹ̀kọ́ 18)
MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI
Kí Ni Géèmù Tó Ò Ń Gbá Ń Sọ Nípa Ẹ?: (7 min.) Ìjíròrò. Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò náà. Lẹ́yìn náà béèrè pé: Kí ló lè ṣẹlẹ̀ sí ẹ tó o bá jẹ́ kí géèmù di bárakú fún ẹ? Àwọn nǹkan wo ló ṣe pàtàkì ju géèmù lọ? (Ef 5:15, 16) Kí nirú géèmù tó ò ń gbá ń sọ nípa ẹ? Ọ̀nà wo ló dáa jù tó o lè gbà lo àkókò ẹ?
“Ṣe Ìpinnu Tó Bọ́gbọ́n Mu Lórí Ọ̀rọ̀ Ọtí”: (8 min.) Ìjíròrò. Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò Má Ṣe Jẹ́ Kí Ọtí Di Ìdẹkùn fún Ẹ.
Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) rr orí 10 ¶1-7 àti fídíò ohun tó wà ní orí 10
Ọ̀rọ̀ Ìparí (3 min.)
Orin 3 àti Àdúrà