ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN
Ṣé Ò Ń Ṣiṣẹ́ Lórí Ohun Tí Ò Ń Kọ́ Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run?
Jòsáyà fara balẹ̀ tẹ́tí sí Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run (2Kr 34:18, 19)
Ó ṣe gbogbo ohun tó lè ṣe kó lè lóye ohun tó gbọ́ nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run (2Kr 34:21; it-1 1157 ¶4; wo àwòrán iwájú ìwé)
Ó ṣiṣẹ́ lórí ohun tó gbọ́ (2Kr 34:33; w09 6/15 10 ¶20)
BI ARA RẸ PÉ, ‘Ṣé mo máa ń tètè ṣiṣẹ́ lórí ohun tí mo kà nípa Jèhófà nínú Bíbélì Ọ̀rọ̀ rẹ̀?’