Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Máa Fi Ojú Tí Jèhófà Fi Ń Wo Àwọn Èèyàn Wò Wọ́n

Máa Fi Ojú Tí Jèhófà Fi Ń Wo Àwọn Èèyàn Wò Wọ́n

Ọba Jèhóṣáfátì hùwà òmùgọ̀ bó ṣe bá Ọba Áhábù da nǹkan pọ̀ (2Kr 18:1-3; w17.03 24 ¶7)

Jèhófà rán Jéhù pé kó lọ bá Jèhóṣáfátì wí (2Kr 19:1, 2)

Jèhófà ò gbàgbé gbogbo àwọn ohun rere tí Jèhóṣáfátì ṣe (2Kr 19:3; w15 8/15 11-12 ¶8-9)

BI ARA RẸ PÉ, ‘Ṣé mo lè fara wé Jèhófà ní ti pé kí n máa wo ibi tí àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin mi dáa sí, dípò kí n gbájú mọ́ àṣìṣe wọn?’