Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

“Ẹ Ní Ìgbàgbọ́ Nínú Jèhófà Ọlọ́run Yín”

“Ẹ Ní Ìgbàgbọ́ Nínú Jèhófà Ọlọ́run Yín”

Nígbà táwọn ọ̀tá ń halẹ̀, Jèhóṣáfátì àtàwọn èèyàn Júdà bẹ Jèhófà pé kó ran àwọn lọ́wọ́ (2Kr 20:12, 13; w14 12/15 23 ¶8)

Jèhófà fi àwọn èèyàn náà lọ́kàn balẹ̀, ó sì fún wọn ní ìtọ́ni tó ṣe kedere (2Kr 20:17)

Jèhófà gba àwọn èèyàn ẹ̀ sílẹ̀ torí wọ́n gbẹ́kẹ̀ lé e (2Kr 20:21, 22, 27; w21.11 16 ¶7)

Tí Gọ́ọ̀gù bá gbéjà ko àwa èèyàn Jèhófà nígbà ìpọ́njú ńlá, àwọn tó bá gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà tí wọ́n sì ń tẹ̀ lé ìtọ́ni àwọn tó yàn láti máa ṣàbójútó kò ní bẹ̀rù ohunkóhun.​—2Kr 20:20.