ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | ONÍWÀÁSÙ 7-12 “Rántí Ẹlẹ́dàá Rẹ Atóbilọ́lá . . . Ní Àwọn Ọjọ́ Tí O Wà Ní Ọ̀dọ́kùnrin” TẸ̀ Ẹ̣́ “Rántí Ẹlẹ́dàá Rẹ Atóbilọ́lá . . . Ní Àwọn Ọjọ́ Tí O Wà Ní Ọ̀dọ́kùnrin” Ọ̀nà tó o lè gbà rántí Ẹlẹ́dàá rẹ Atóbilọ́lá ni pé kó o ṣiṣẹ́ sìn ín nígbà tí eegun ọ̀dọ́ ṣì wà 12:1, 13 Ọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ ló ní okun àti agbára láti bójú tó iṣẹ́ tó lágbára tó sì gba àròjinlẹ̀ Ó yẹ kí àwọn ọ̀dọ́ lo àkókò àti okun wọn lẹ́nu iṣẹ́ ìsìn Ọlọ́run kí ọjọ́ ogbó tó dín agbára wọn kù Sólómọ́nì lo ewì láti ṣàpèjúwe ìṣòro tí àwọn arúgbó máa ń ní 12:2-7 Ẹsẹ 3: “Àwọn ọmọge tí ń wòde lójú fèrèsé sì rí i pé òkùnkùn ṣú” Ojú tó ti di bàìbàì Ẹsẹ 4: “Àwọn ọmọbìnrin orin ń dún lọ́nà rírẹlẹ̀” Etí tí kò gbọ́ràn dáadáa Ẹsẹ 5: “Àgbáyun kápérì sì bẹ́” Oúnjẹ tí kò lọ lẹ́nu Pa Dà Èyí Tó Kàn Tẹ̀ ẹ́ Fi ránṣẹ́ Fi ránṣẹ́ “Rántí Ẹlẹ́dàá Rẹ Atóbilọ́lá . . . Ní Àwọn Ọjọ́ Tí O Wà Ní Ọ̀dọ́kùnrin” ÌWÉ ÌPÀDÉ ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ ÀWA KRISTẸNI “Rántí Ẹlẹ́dàá Rẹ Atóbilọ́lá . . . Ní Àwọn Ọjọ́ Tí O Wà Ní Ọ̀dọ́kùnrin” Yorùbá “Rántí Ẹlẹ́dàá Rẹ Atóbilọ́lá . . . Ní Àwọn Ọjọ́ Tí O Wà Ní Ọ̀dọ́kùnrin” https://cms-imgp.jw-cdn.org/img/p/202016410/univ/art/202016410_univ_sqr_xl.jpg