ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | ORIN SÓLÓMỌ́NÌ 1-8 Ọmọbìnrin Ṣúlámáítì Jẹ́ Àpẹẹrẹ Rere Tá A Lè Tẹ̀ Lé TẸ̀ Ẹ̣́ Ọmọbìnrin Ṣúlámáítì Jẹ́ Àpẹẹrẹ Rere Tá A Lè Tẹ̀ Lé Kí ló mú kí ọ̀dọ́bìnrin yìí jẹ́ àpẹẹrẹ tó tayọ fún àwọn tó ń jọ́sìn Jèhófà? 2:7; 4:12 Ó hùwà ọgbọ́n láti dúró dìgbà tó máa fi rí ẹni tí wọ́n á jọ nífẹ̀ẹ́ ara wọn tọkàntọkàn Kò jẹ́ kí ohun táwọn míì ń sọ mú kó bẹ̀rẹ̀ sí í nífẹ̀ẹ́ ẹnikẹ́ni tó bá ṣáà ti kọ ẹnu ìfẹ́ sí i Ó lẹ́mìí ìrẹ̀lẹ̀, ó mọ̀wọ̀n ara ẹ̀, ó sì níwà mímọ́ Kò jẹ́ kí góòlù tàbí ọ̀rọ̀ dídùn kó sí òun lórí Bi ara rẹ pé: ‘Èwo lára àwọn ànímọ́ Ṣúlámáítì ni mo máa fara wé?’ Pa Dà Èyí Tó Kàn Tẹ̀ ẹ́ Fi ránṣẹ́ Fi ránṣẹ́ Ọmọbìnrin Ṣúlámáítì Jẹ́ Àpẹẹrẹ Rere Tá A Lè Tẹ̀ Lé ÌWÉ ÌPÀDÉ ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ ÀWA KRISTẸNI Ọmọbìnrin Ṣúlámáítì Jẹ́ Àpẹẹrẹ Rere Tá A Lè Tẹ̀ Lé Yorùbá Ọmọbìnrin Ṣúlámáítì Jẹ́ Àpẹẹrẹ Rere Tá A Lè Tẹ̀ Lé https://cms-imgp.jw-cdn.org/img/p/202016413/univ/art/202016413_univ_sqr_xl.jpg