ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN
Bí Jóòbù Ṣe Fi Hàn Pé Òun Jẹ́ Oníwà Mímọ́
Jóòbù bá ojú rẹ̀ dá májẹ̀mú (Job 31:1; w10 4/15 21 ¶8)
Jóòbù ronú lórí ohun tó máa jẹ́ àbájáde ìwà tí ò dáa (Job 31:2, 3; w08 9/1 11 ¶4)
Jóòbù fi sọ́kàn pé Ọlọ́run ń rí gbogbo ohun tóun ń ṣe (Job 31:4; w10 11/15 5-6 ¶15-16)
Ká jẹ́ mímọ́ kọjá pé ká kàn mọ́ lóde ara nìkan, ó tún kan irú ẹni tá a jẹ́ ní inú. Kódà, a gbọ́dọ̀ sapá láti gbé èròkerò kúrò lọ́kàn wa.—Mt 5:28.