Àwọn ará ń fìfẹ́ hàn síra wọn ní Màláwì

ÌWÉ ÌPÀDÉ ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ ÀWA KRISTẸNI October 2018

Ohun Tá A Lè Bá Àwọn Èèyàn Sọ

Ìjíròrò tó dá lórí ìdí tí àwa èèyàn fi ń jìyà àti ohun tí Ọlọ́run fẹ́ ṣe nípa rẹ̀.

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Jésù Ń Bójú Tó Àwọn Àgùntàn Rẹ̀

Jésù tó jẹ́ Olùṣọ́ Àgùntàn Àtàtà mọ àwọn àgùntàn rẹ̀ lọ́kọ̀ọ̀kan, ó mọ ohun tí wọ́n nílò, ibi tí wọ́n kù sí àti ibi tí wọ́n dáa sí.

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Máa Tu Àwọn Mí ì Nínú Bí I Ti Jésù

Kí ló mú kí ojú àánú tí Jésù ní ṣàrà ọ̀tọ̀?

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

“Mo Fi Àwòṣe Lélẹ̀ fún Yín”

Jésù kọ́ àwọn àpọ́sítélì rẹ̀ pé kí wọ́n jẹ́ onírẹ̀lẹ̀ kí wọ́n sì máa ṣe àwọn iṣẹ́ tó rẹlẹ̀ fún àwọn arákùnrin wọn.

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

Ìfẹ́ Ni A Fi Ń Dá Àwọn Kristẹni Tòótọ́ Mọ̀—Kọ Ìmọtara-Ẹni-Nìkan àti Ìbínú Sílẹ̀

Tá a bá fẹ́ nífẹ̀ẹ́ àwọn ará wa bí Kristi ṣe nífẹ̀ẹ́ wọn, àfi ká máa wá bí nǹkan ṣe máa dáa fún wọn, ká sì máa mú sùúrù fún wọn.

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

“Ẹ Kì Í Ṣe Apá Kan Ayé”

Àwọn ọmọlẹ́yìn Jésù nílò ìgboyà kí wọ́n má bàa jẹ́ kí àwọn èèyàn tó wà nínú ayé yìí sọ wọ́n di bí wọ́n ṣe dà.

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

Ìfẹ́ Ni A Fi Ń Dá Àwọn Kristẹni Tòótọ́ Mọ̀​—Yẹra fún Ohun Tó Lè Ba Ìṣọ̀kan Jẹ́

Kí ìṣọ̀kan tó wà láàárín wa má bàa dà rú, a gbọ́dọ̀ máa wá ibi táwọn ará wa dáa sí, ká sì máa dárí jì wọ́n fàlàlà.

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Jésù Jẹ́rìí sí Òtítọ́

Àwa tá a jẹ́ ọmọlẹ́yìn Jésù náà máa ń jẹ́rìí sí òtítọ́ nínú ọ̀rọ̀ àti ìṣe.

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

Ìfẹ́ Ni A Fi Ń Dá Àwọn Kristẹni Tòótọ́ Mọ̀​—Máa Yọ̀ Pẹ̀lú Òtítọ́

Láìka ti pé inú ayé tó kún fún irọ́ àti ìwà àìṣòdodo là ń gbé, a gbọ́dọ̀ máa yọ̀ pẹ̀lú òtítọ́, ká máa sọ òtítọ́, ká sì máa ronú lórí ohun yòówù tí ó jẹ́ òtítọ́.