Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

July 8, 2005

Bó O Ṣe Lè Rí Iṣẹ́ Tí Iṣẹ́ Náà Ò sì Ní Bọ́ Lọ́wọ́ Rẹ

Lóde òní táwọn tó ń wáṣẹ́ ti pọ̀ bí rẹ́rẹ yìí, ọ̀rọ̀ àìníṣẹ́lọ́wọ́ ti dogun. Àwọn nǹkan wo lo lè ṣe tí wàá fi ríṣẹ́, tí iṣẹ́ ọ̀hún ò sì ní bọ́ lọ́wọ́ rẹ?

3 Iṣẹ́ Bọ́!

4 Nǹkan Márùn-ún Tó O Lè Ṣe Láti Ríṣẹ́

10 Ohun Tó O Lè Ṣe Tí Iṣẹ́ Ò Fi Ní Bọ́ Mọ́ Ẹ Lọ́wọ́

15 Ṣíṣàfọwọ́rá Ṣé Eré Ọwọ́ Ni Àbí Ìwà Ọ̀daràn?

16 Kí Ló Ń máwọn Èèyàn Ṣàfọwọ́rá?

18 Ta Ló Ń forí Fá Àtúbọ̀tán Ṣíṣàfọwọ́rá?

21 Bá A Ṣe Lè Fòpin Sí Ṣíṣàfọwọ́rá

23 “A Kì Í Sọ̀rọ̀ Àlùfààṣá Lédè Tiwa”

26 Mo Pinnu Pé Mo Gbọ́dọ̀ Bá Ohun Tí Mò Ń Lé

28 Bí Wọ́n Ṣe Ń Gbe Omi Òjò Látijọ́ Àti Lóde Òní

32 Wá Kọ́ nípa ohun tí Bíbélì Sọ

Kí Ló Yẹ Kí N Ṣe Bí Ọ̀dọ́bìnrin Kan Bá Dẹnu Ìfẹ́ Kọ Mí? 12

Ó lè yà ẹ́ lẹ́nu, ó lè dùn mọ́ ẹ nínú, tàbí kó tì ẹ́ lójú tó o bá gbọ́ tẹ́nì kan sọ irú ẹ̀ sí ọ, àmọ́ kí lo máa ṣe?

Ṣó Yẹ Kó O Máa Bẹ̀rù Amágẹ́dọ́nì? 24

Oríṣiríṣi èrò òdì làwọn èèyàn ní nípa Amágẹ́dọ́nì. Ojú wo ló yẹ ká fi wo ohun tí Bíbélì sọ nípa Amágẹ́dọ́nì?