Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Kí Ni Ìdáhùn Rẹ?

Kí Ni Ìdáhùn Rẹ?

Kí Ni Ìdáhùn Rẹ?

Ibo Ni Ìṣẹ̀lẹ̀ Yìí Ti Wáyé?

1. Ìlú wo ní ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ti wáyé?

AMỌ̀NÀ: Ka Ìṣe 2:1-13.

Fa ilà yípo ìdáhùn rẹ nínú àwòrán ilẹ̀.

Áténì

Jerúsálẹ́mù

Bábílónì

◼ Ibo lọ̀pọ̀ jù lọ lára àwọn ọmọ ẹ̀yìn ti wá?

․․․․․

◼ Kí nìdí táwọn kan fi fàwọn ọmọ ẹ̀yìn ṣẹlẹ́yà?

․․․․․

FÚN ÌJÍRÒRÒ:

Ìyàtọ̀ wo ló wà nínú ìṣẹ̀lẹ̀ yìí àtèyí tí àkọsílẹ̀ rẹ̀ wà nínú Jẹ́nẹ́sísì 11:1-9, báwo ni wọ́n sì ṣe jọra?

Nínú Ìtẹ̀jáde Yìí

Dáhùn àwọn ìbéèrè yìí, kó o sì kọ (àwọn) ẹsẹ Bíbélì tó yẹ sínú àlàfo.

OJÚ ÌWÉ 14 Kí làwọn kan tó ní ìtara fún Ọlọ́run ò ní? Róòmù 10:․․․

OJÚ ÌWÉ 15 Ta ló yẹ ká ṣègbọràn sí? Ìṣe 5:․․․

Kí Lo Mọ̀ Nípa Ótíníẹ́lì Onídàájọ́?

Ka Àwọn Onídàájọ́ 3:7-11. Wá dáhùn àwọn ìbéèrè tó tẹ̀ lé e wọ̀nyí.

2. ․․․․․

Ẹ̀yà wo ló ti wá?

AMỌ̀NÀ: Ka Jóṣúà 15:17, 20.

3. ․․․․․

Ọwọ́ alákòóso wo ló ti dá Ísírẹ́lì nídè?

4. ․․․․․

Bẹ́ẹ̀ ni tàbí rárá? Ó gbé láyé ṣáájú Mósè.

FÚN ÌJÍRÒRÒ:

Àpẹẹrẹ rere wo ni Kálébù tó jẹ́ èèyàn òbí Ótíníẹ́lì fi lélẹ̀?

AMỌ̀NÀ: Ka Númérì 14:6-9. Kọ orúkọ ìbátan ẹ kan tó o gba tìẹ sílẹ̀, kó o sì ṣàlàyé nǹkan tó wú ẹ lórí nípa ẹ̀.

ÌDÁHÙN ÀWỌN ÌBÉÈRÈ

1. Jerúsálẹ́mù.—Ìṣe 2:5.

◼ Gálílì.—Ìṣe 2:7.

◼ Wọ́n rò pé wọ́n ti mutí yó.—Ìṣe 2:13.

2. Júdà.—Jóṣúà 15:17, 20.

3. Kuṣani-ríṣátáímù.—Àwọn Onídàájọ́ 3:8.

4. Rárá.