Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Atọ́ka Àwọn Àkòrí fún Ilé Ìṣọ́ 2017

Atọ́ka Àwọn Àkòrí fún Ilé Ìṣọ́ 2017

Ó ń tọ́ka sí Ilé Ìṣọ́ tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde

ÀWA ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ

  • A Ó Bù Kún Ẹni Tí Ó Jẹ́ Ọ̀làwọ́ (ọrẹ), Nov.

  • Ayọ̀ Tó Wà Nínú Kéèyàn Jẹ́ Kí Ohun Ìní Díẹ̀ Tẹ́ Òun Lọ́rùn, May

  • Bí Ara Ẹ Ṣe Lè Mọlé Nínú Ìjọ Tó O Wà Báyìí, Nov.

  • “Ìgbà Wo La Tún Máa Ṣe Àpéjọ Míì?” (Mẹ́síkò), Aug.

  • “Kò Sí Ọ̀nà Tó Burú Jù Tàbí Jìn Jù” (Ọsirélíà), Feb.

  • Oore Kan Tó Sèso Rere, Oct.

  • ‘Wọ́n Fìtara Wàásù Ju Ti Tẹ́lẹ̀ Lọ’ (àpéjọ àgbègbè ọdún 1922), May

  • Wọ́n Yọ̀ǹda Ara Wọn ní Tọ́kì, July

  • Wọ́n Yọ̀ǹda Ara Wọn Tinútinú (àwọn arábìnrin tí kò tíì lọ́kọ), Jan.

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

  • ‘Àlàáfíà Ọlọ́run Ta Gbogbo Ìrònú Yọ,’ Aug.

  • Àwọn Kẹ̀kẹ́ Ẹṣin àti Adé Kan Ń Dáàbò Bò Ẹ́, Oct.

  • Àwọn Nǹkan Wo Ló Máa Lọ tí Ìjọba Ọlọ́run Bá Dé? Apr.

  • Bá A Ṣe Lè Bọ́ Àwọn Ìwà Àtijọ́ Sílẹ̀, Ká Má sì Gbé E Wọ̀ Mọ́, Aug.

  • Bá A Ṣe Lè Gbé Àkópọ̀ Ìwà Tuntun Wọ̀, Tá Ò sì Ní Bọ́ Ọ Sílẹ̀ Mọ́, Aug.

  • Bá A Ṣe Lè Ní Ọrọ̀ Tòótọ́, July

  • Bá A Ṣe Lè Ran Àwọn Àjèjì Lọ́wọ́ Kí Wọ́n Lè Máa ‘Fayọ̀ Sin Jèhófà,’ May

  • Bá A Ṣe Lè Ṣèrànwọ́ Fáwọn Ọmọ Tí Òbí Wọn Jẹ́ Àjèjì, May

  • Bí Àwọn Ìran Tí Sekaráyà Rí Ṣe Kàn Ẹ́, Oct.

  • Ẹ Má Ṣe Jẹ́ Kí Ìfẹ́ Yín Di Tútù, May

  • Ẹ Máa Bọlá fún Àwọn Tí Ọlá Tọ́ Sí, Mar.

  • ‘Ẹ Máa Sunkún Pẹ̀lú Àwọn Tí Ń Sunkún,’ July

  • Ẹ̀yin Òbí​—Ẹ Ran Àwọn Ọmọ Yín Lọ́wọ́ Kí Wọ́n Lè “Di Ọlọ́gbọ́n fún Ìgbàlà,” Dec.

  • Ẹ̀yin Ọ̀dọ́​—“Ẹ Máa Ṣiṣẹ́ Ìgbàlà Yín Yọrí,” Dec.

  • Fara Mọ́ Ìṣàkóso Jèhófà! June

  • Fi ‘Nǹkan Wọ̀nyí Lé Àwọn Olùṣòtítọ́ Lọ́wọ́,’ Jan.

  • Fi Ọkàn Pípé Pérépéré Sin Jèhófà! Mar.

  • “Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà, Kí O sì Máa Ṣe Rere,” Jan.

  • Idà Ni Òtítọ́ Ń Mú Wá, Kì Í Ṣe Àlàáfíà, Oct.

  • Ìdí Tó Fi Yẹ Ká Jẹ́ Ẹni Tó Mẹ̀tọ́mọ̀wà, Jan.

  • Ìràpadà​—“Ọrẹ Pípé” Tí Baba Fún Wa, Feb.

  • “Ìwọ Ha Nífẹ̀ẹ́ Mi Ju Ìwọ̀nyí Lọ Bí?” May

  • Jèhófà Máa Jẹ́ Kí Àwọn Ìpinnu Rẹ Yọrí Sí Rere, July

  • Jèhófà Ń Darí Àwọn Èèyàn Rẹ̀, Feb.

  • Jèhófà Ń Tù Wá Nínú Nínú Gbogbo Ìpọ́njú Wa, June

  • “Jẹ́ Onígboyà . . . Kí O sì Gbé Ìgbésẹ̀” Sept.

  • “Kí A Nífẹ̀ẹ́ . . . ní Ìṣe àti Òtítọ́,” Oct.

  • Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Ká Máa Yin Jèhófà? July

  • Lo Ìgbàgbọ́ Kó O Lè Ṣe Ìpinnu Tó Mọ́gbọ́n Dání! Mar.

  • Má Ṣe Fàyè Gba Èrò Ayé, Nov.

  • Má Ṣe Jẹ́ Kí Ohunkóhun Mú Kó O Pàdánù Èrè Ọjọ́ Iwájú, Nov.

  • Máa Fàánú Hàn Bíi Ti Jèhófà, Sept.

  • Máa Fàánú Hàn, Kó O sì Máa Ṣe Ìdájọ́ Òdodo Bíi Ti Jèhófà, Nov.

  • Máa Fi Ayọ̀ Kọrin! Nov.

  • Máa Fọkàn sí Àwọn Ìṣúra Tẹ̀mí, June

  • Máa Kó Ara Rẹ Níjàánu, Sept.

  • “Mo Mọ̀ Pé Yóò Dìde,” Dec.

  • “Mo Ní Ìrètí Sọ́dọ̀ Ọlọ́run,” Dec.

  • Mọyì Òmìnira Tó O Ní, Jan.

  • O Lè Jẹ́ Amẹ̀tọ́mọ̀wà Bí Kò Bá Tiẹ̀ Rọrùn, Jan.

  • Ohun Tí Jèhófà Ní Lọ́kàn Máa Ṣẹ! Feb.

  • “Ohun Tí O Jẹ́jẹ̀ẹ́, San Án,” Apr.

  • ‘Onídàájọ́ Ilẹ̀ Ayé’ Máa Ń Ṣe Ohun Tó Tọ́ Nígbà Gbogbo, Apr.

  • “Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run . . . Ń Sa Agbára,” Sept.

  • Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run Yóò Wà Títí Láé, Sept.

  • Pọkàn Pọ̀ Sórí Ọ̀rọ̀ Tó Ṣe Pàtàkì Jù, June

  • Ṣé Èrò Tí Jèhófà Ní Nípa Ìdájọ́ Òdodo Ni Ìwọ Náà Ní? Apr.

  • Ṣé Ò Ń Sá Di Jèhófà? Nov.

  • Ṣé Wàá Fọkàn sí Àwọn Ohun Tá A Ti Kọ Sílẹ̀? Mar.

  • Ṣé Wàá Lè Fi Sùúrù Dúró De Jèhófà? Aug.

  • Ta Ló Ń Darí Àwa Èèyàn Ọlọ́run Lónìí? Feb.

  • Yọ̀ǹda Ara Rẹ Tinútinú, Kí Ìyìn Lè Jẹ́ ti Jèhófà! Apr.

BÍBÉLÌ

  • Bó O Ṣe Lè Rí Ẹ̀kọ́ Kọ́ Látinú Kíka Bíbélì, No. 1

  • Elias Hutter Ṣiṣẹ́ Ribiribi Sínú Àwọn Bíbélì Èdè Hébérù Tó Ṣe, No. 4

  • Ewu Tó Wà Nínú Kéèyàn Ṣi Bíbélì Lóye, No. 1

  • Ẹ̀rí Míì Tún Rèé (Táténáì wà lóòótọ́), No. 3

  • Kí Nìdí Tí Oríṣiríṣi Bíbélì Fi Wà? No. 6

BÍBÉLÌ MÁA Ń YÍ ÌGBÉSÍ AYÉ ÀWỌN ÈÈYÀN PA DÀ

  • Mi Ò Fẹ́ Kú O! (Y. Quarrie), No. 1

  • Mo Fẹ́ràn Baseball Gan-an! (S. Hamilton), No. 3

  • Ní Tèmi O, Kò Sí Ọlọ́run (A. Golec), No. 5

ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ

  • Jèhófà Kò Ní “Jẹ́ Kí A Dẹ Yín Wò Ré Kọjá Ohun Tí Ẹ Lè Mú Mọ́ra” (1Kọ 10:13), Feb.

  • Kí Nìdí Tí Ohun Tí Mátíù àti Lúùkù Sọ Nípa Ìgbà Tí Jésù Wà Ní Kékeré Fi Yàtọ̀ Síra? Aug.

  • Ǹjẹ́ Àwọn Tọkọtaya Kristẹni Lè Lo Ìfètòsọ́mọbíbí Kan Tí Wọ́n Ń Pè Ní IUD? Dec.

  • Ṣé Ìgbà Gbogbo Ni Ìlà Ìdílé Tí Mèsáyà Ti Wá Máa Ń Gba Ọ̀dọ̀ Àkọ́bí Ọkùnrin Kọjá? Dec.

  • Ṣé Ó Yẹ Kí Kristẹni Ní Ìbọn? July

ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI

  • Èrè Tó Wà Nínú Fífúnni, No. 2

  • Èrò Tó Yẹ Ká Ní Nípa Àṣìṣe, No. 6

  • Ìfẹ́​—Ànímọ́ Kan Tó Ṣe Pàtàkì, Aug.

  • Má Ṣe Jẹ́ Kí Sátánì Tàn Ẹ́ Jẹ, July

  • Ṣé Ó Pọn Dandan Kí Kristẹni Òjíṣẹ́ Wà Láìgbéyàwó? No. 2

  • Ṣé Ó Yẹ Káwọn Kristẹni Máa Ṣe Ọdún Kérésìmesì? No. 6

  • Tí Àárín Ìwọ àti Ọ̀rẹ́ Rẹ Bá Fẹ́ Dàrú, Mar.

  • Yanjú Èdèkòyédè Kí Àlàáfíà Lè Jọba, June

ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ

  • A Fara Da Ìpọ́njú, Jèhófà sì Bù Kún Wa (P. Sivulsky), Aug.

  • Bí Mo Tiẹ̀ Jẹ́ Adití, Mò Ń Kọ́ Àwọn Míì Lẹ́kọ̀ọ́ (W. Markin), May

  • Inú Mi Dùn Pé Mo Bá Àwọn Tó Nífẹ̀ẹ́ Jèhófà Ṣiṣẹ́ (D. Sinclair), Sept.

  • Jèhófà Fi Inú Rere Àìlẹ́tọ̀ọ́sí Hàn sí Wa Lónírúurú Ọ̀nà (D. Guest), Feb.

  • Jèhófà Máa Ń Bù Kún Àwọn Tó Bá Ṣe Ìfẹ́ Rẹ̀ (O. Matthews), Oct.

  • Mo Bá Àwọn Ọlọ́gbọ́n Rìn, Mo sì Kẹ́kọ̀ọ́ Lára Wọn (W. Samuelson), Mar.

  • Mo Fi Àwọn Nǹkan Sílẹ̀ Kí N Lè Tẹ̀ Lé Jésù (F. Fajardo), Dec.

  • Mo Pinnu Pé Ọmọ Ogun Kristi Ni Màá Jẹ́ (D. Psarras), Apr.

JÈHÓFÀ

  • Gba Ẹ̀bùn Ọlọ́run Tó Dára Jù, No. 2

  • Ṣé Ọlọ́run Ló Ń Fa Ìjìyà? No. 1

JÉSÙ KRISTI

  • Àpèjúwe Tí Jésù Ṣe Nípa “Ajá Kéékèèké,” No. 5

  • Báwo Ni Jésù Ṣe Rí Gan-an? No. 6

Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN

  • Àbá Tí Àpọ́sítélì Pọ́ọ̀lù Fún Àwọn Atukọ̀ Òkun (Iṣe 27), No. 5

  • Àníyàn, No. 4

  • Báwo Ni Wọ́n Ṣe Ń Mú Iná Láti Ibì Kan dé Ibòmíì Láyé Àtijọ́? Jan.

  • Bí Gáyọ́sì Ṣe Ran Àwọn Ará Lọ́wọ́, May

  • Ẹ̀bùn Tó Dáa Ju Gbogbo Ẹ̀bùn Lọ, No. 6

  • Ẹlẹ́ṣin Mẹ́rin, No. 3

  • ‘Ìbùkún Ni fún Ìlóyenínú Rẹ’ (Ábígẹ́lì), June

  • Ìjìyà, No. 1

  • Jósẹ́fù ará Arimatíà, Oct.

  • Kí Ni Amágẹ́dọ́nì? No. 6

  • Kí Nìdí Tí Jésù Fi Dẹ́bi fún Àwọn Tó Ń Búra? Oct.

  • Lẹ́tà Èdè Hébérù Tó Kéré Jù Lọ, No. 4

  • Ǹjẹ́ Àkókò Kan Ń Bọ̀ Tí Gbogbo Èèyàn Á Máa Ṣe Ìdájọ́ Òdodo? No. 3

  • Ohun Tí Bíbélì Sọ Nípa Ìyè àti Ikú, No. 4

  • “O Jẹ́ Obìnrin Kan Tí Ó Lẹ́wà ní Ìrísí” (Sárà), No. 3

  • Orúkọ Bíbélì Kan Tó Wà Lára Ìkòkò, Mar.

  • “Ó Ti Wu Ọlọ́run Dáadáa” (Énọ́kù), No. 1

  • Òwò Ẹrú, No. 2

  • Ọkàn Àwọn Èèyàn Ló Ṣe Pàtàkì, June

  • Ọlọ́run Pè É Ní “Ìyá Ọba” (Sárà), No. 5

  • Ṣé Àlááfíà Ṣì Máa Wà Láyé? No. 5

  • Ṣé Àwọn Áńgẹ́lì Wà Lóòótọ́? No. 5

  • Ṣé “Àwọn Ọjọ́ Ìkẹyìn” Là Ń Gbé Báyìí? No. 2

  • Ṣé Ayé Máa Di Párádísè Lóòótọ́? No. 4

  • Ṣé Lóòótọ́ La Lè Pe Àwọn Oníṣòwò Tó Ń Tajà Nínú Tẹ́ńpìlì Jerúsálẹ́mù Ní “Ọlọ́ṣà”? June

  • Tí Àìsàn Gbẹ̀mí-Gbẹ̀mí Bá Ń Ṣe Ẹni Tá A Nífẹ̀ẹ́, No. 4