Atọ́ka Àwọn Àkòrí fún Ilé Ìṣọ́ 2017
Ó ń tọ́ka sí Ilé Ìṣọ́ tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde
ÀWA ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ
A Ó Bù Kún Ẹni Tí Ó Jẹ́ Ọ̀làwọ́ (ọrẹ), Nov.
Ayọ̀ Tó Wà Nínú Kéèyàn Jẹ́ Kí Ohun Ìní Díẹ̀ Tẹ́ Òun Lọ́rùn, May
Bí Ara Ẹ Ṣe Lè Mọlé Nínú Ìjọ Tó O Wà Báyìí, Nov.
“Ìgbà Wo La Tún Máa Ṣe Àpéjọ Míì?” (Mẹ́síkò), Aug.
“Kò Sí Ọ̀nà Tó Burú Jù Tàbí Jìn Jù” (Ọsirélíà), Feb.
Oore Kan Tó Sèso Rere, Oct.
‘Wọ́n Fìtara Wàásù Ju Ti Tẹ́lẹ̀ Lọ’ (àpéjọ àgbègbè ọdún 1922), May
Wọ́n Yọ̀ǹda Ara Wọn ní Tọ́kì, July
Wọ́n Yọ̀ǹda Ara Wọn Tinútinú (àwọn arábìnrin tí kò tíì lọ́kọ), Jan.
ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
‘Àlàáfíà Ọlọ́run Ta Gbogbo Ìrònú Yọ,’ Aug.
Àwọn Kẹ̀kẹ́ Ẹṣin àti Adé Kan Ń Dáàbò Bò Ẹ́, Oct.
Àwọn Nǹkan Wo Ló Máa Lọ tí Ìjọba Ọlọ́run Bá Dé? Apr.
Bá A Ṣe Lè Bọ́ Àwọn Ìwà Àtijọ́ Sílẹ̀, Ká Má sì Gbé E Wọ̀ Mọ́, Aug.
Bá A Ṣe Lè Gbé Àkópọ̀ Ìwà Tuntun Wọ̀, Tá Ò sì Ní Bọ́ Ọ Sílẹ̀ Mọ́, Aug.
Bá A Ṣe Lè Ní Ọrọ̀ Tòótọ́, July
Bá A Ṣe Lè Ran Àwọn Àjèjì Lọ́wọ́ Kí Wọ́n Lè Máa ‘Fayọ̀ Sin Jèhófà,’ May
Bá A Ṣe Lè Ṣèrànwọ́ Fáwọn Ọmọ Tí Òbí Wọn Jẹ́ Àjèjì, May
Bí Àwọn Ìran Tí Sekaráyà Rí Ṣe Kàn Ẹ́, Oct.
Ẹ Má Ṣe Jẹ́ Kí Ìfẹ́ Yín Di Tútù, May
Ẹ Máa Bọlá fún Àwọn Tí Ọlá Tọ́ Sí, Mar.
‘Ẹ Máa Sunkún Pẹ̀lú Àwọn Tí Ń Sunkún,’ July
Ẹ̀yin Òbí—Ẹ Ran Àwọn Ọmọ Yín Lọ́wọ́ Kí Wọ́n Lè “Di Ọlọ́gbọ́n fún Ìgbàlà,” Dec.
Ẹ̀yin Ọ̀dọ́—“Ẹ Máa Ṣiṣẹ́ Ìgbàlà Yín Yọrí,” Dec.
Fara Mọ́ Ìṣàkóso Jèhófà! June
Fi ‘Nǹkan Wọ̀nyí Lé Àwọn Olùṣòtítọ́ Lọ́wọ́,’ Jan.
Fi Ọkàn Pípé Pérépéré Sin Jèhófà! Mar.
“Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà, Kí O sì Máa Ṣe Rere,” Jan.
Idà Ni Òtítọ́ Ń Mú Wá, Kì Í Ṣe Àlàáfíà, Oct.
Ìdí Tó Fi Yẹ Ká Jẹ́ Ẹni Tó Mẹ̀tọ́mọ̀wà, Jan.
Ìràpadà—“Ọrẹ Pípé” Tí Baba Fún Wa, Feb.
“Ìwọ Ha Nífẹ̀ẹ́ Mi Ju Ìwọ̀nyí Lọ Bí?” May
Jèhófà Máa Jẹ́ Kí Àwọn Ìpinnu Rẹ Yọrí Sí Rere, July
Jèhófà Ń Darí Àwọn Èèyàn Rẹ̀, Feb.
Jèhófà Ń Tù Wá Nínú Nínú Gbogbo Ìpọ́njú Wa, June
“Jẹ́ Onígboyà . . . Kí O sì Gbé Ìgbésẹ̀” Sept.
“Kí A Nífẹ̀ẹ́ . . . ní Ìṣe àti Òtítọ́,” Oct.
Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Ká Máa Yin Jèhófà? July
Lo Ìgbàgbọ́ Kó O Lè Ṣe Ìpinnu Tó Mọ́gbọ́n Dání! Mar.
Má Ṣe Fàyè Gba Èrò Ayé, Nov.
Má Ṣe Jẹ́ Kí Ohunkóhun Mú Kó O Pàdánù Èrè Ọjọ́ Iwájú, Nov.
Máa Fàánú Hàn Bíi Ti Jèhófà, Sept.
Máa Fàánú Hàn, Kó O sì Máa Ṣe Ìdájọ́ Òdodo Bíi Ti Jèhófà, Nov.
Máa Fi Ayọ̀ Kọrin! Nov.
Máa Fọkàn sí Àwọn Ìṣúra Tẹ̀mí, June
Máa Kó Ara Rẹ Níjàánu, Sept.
“Mo Mọ̀ Pé Yóò Dìde,” Dec.
“Mo Ní Ìrètí Sọ́dọ̀ Ọlọ́run,” Dec.
Mọyì Òmìnira Tó O Ní, Jan.
O Lè Jẹ́ Amẹ̀tọ́mọ̀wà Bí Kò Bá Tiẹ̀ Rọrùn, Jan.
Ohun Tí Jèhófà Ní Lọ́kàn Máa Ṣẹ! Feb.
“Ohun Tí O Jẹ́jẹ̀ẹ́, San Án,” Apr.
‘Onídàájọ́ Ilẹ̀ Ayé’ Máa Ń Ṣe Ohun Tó Tọ́ Nígbà Gbogbo, Apr.
“Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run . . . Ń Sa Agbára,” Sept.
Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run Yóò Wà Títí Láé, Sept.
Pọkàn Pọ̀ Sórí Ọ̀rọ̀ Tó Ṣe Pàtàkì Jù, June
Ṣé Èrò Tí Jèhófà Ní Nípa Ìdájọ́ Òdodo Ni Ìwọ Náà Ní? Apr.
Ṣé Ò Ń Sá Di Jèhófà? Nov.
Ṣé Wàá Fọkàn sí Àwọn Ohun Tá A Ti Kọ Sílẹ̀? Mar.
Ṣé Wàá Lè Fi Sùúrù Dúró De Jèhófà? Aug.
Ta Ló Ń Darí Àwa Èèyàn Ọlọ́run Lónìí? Feb.
Yọ̀ǹda Ara Rẹ Tinútinú, Kí Ìyìn Lè Jẹ́ ti Jèhófà! Apr.
BÍBÉLÌ
BÍBÉLÌ MÁA Ń YÍ ÌGBÉSÍ AYÉ ÀWỌN ÈÈYÀN PA DÀ
ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ
Jèhófà Kò Ní “Jẹ́ Kí A Dẹ Yín Wò Ré Kọjá Ohun Tí Ẹ Lè Mú Mọ́ra” (1Kọ 10:13), Feb.
Kí Nìdí Tí Ohun Tí Mátíù àti Lúùkù Sọ Nípa Ìgbà Tí Jésù Wà Ní Kékeré Fi Yàtọ̀ Síra? Aug.
Ǹjẹ́ Àwọn Tọkọtaya Kristẹni Lè Lo Ìfètòsọ́mọbíbí Kan Tí Wọ́n Ń Pè Ní IUD? Dec.
Ṣé Ìgbà Gbogbo Ni Ìlà Ìdílé Tí Mèsáyà Ti Wá Máa Ń Gba Ọ̀dọ̀ Àkọ́bí Ọkùnrin Kọjá? Dec.
Ṣé Ó Yẹ Kí Kristẹni Ní Ìbọn? July
ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI
Èrè Tó Wà Nínú Fífúnni, No. 2
Èrò Tó Yẹ Ká Ní Nípa Àṣìṣe, No. 6
Ìfẹ́—Ànímọ́ Kan Tó Ṣe Pàtàkì, Aug.
Má Ṣe Jẹ́ Kí Sátánì Tàn Ẹ́ Jẹ, July
Ṣé Ó Pọn Dandan Kí Kristẹni Òjíṣẹ́ Wà Láìgbéyàwó? No. 2
Ṣé Ó Yẹ Káwọn Kristẹni Máa Ṣe Ọdún Kérésìmesì? No. 6
Tí Àárín Ìwọ àti Ọ̀rẹ́ Rẹ Bá Fẹ́ Dàrú, Mar.
Yanjú Èdèkòyédè Kí Àlàáfíà Lè Jọba, June
ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ
A Fara Da Ìpọ́njú, Jèhófà sì Bù Kún Wa (P. Sivulsky), Aug.
Bí Mo Tiẹ̀ Jẹ́ Adití, Mò Ń Kọ́ Àwọn Míì Lẹ́kọ̀ọ́ (W. Markin), May
Inú Mi Dùn Pé Mo Bá Àwọn Tó Nífẹ̀ẹ́ Jèhófà Ṣiṣẹ́ (D. Sinclair), Sept.
Jèhófà Fi Inú Rere Àìlẹ́tọ̀ọ́sí Hàn sí Wa Lónírúurú Ọ̀nà (D. Guest), Feb.
Jèhófà Máa Ń Bù Kún Àwọn Tó Bá Ṣe Ìfẹ́ Rẹ̀ (O. Matthews), Oct.
Mo Bá Àwọn Ọlọ́gbọ́n Rìn, Mo sì Kẹ́kọ̀ọ́ Lára Wọn (W. Samuelson), Mar.
Mo Fi Àwọn Nǹkan Sílẹ̀ Kí N Lè Tẹ̀ Lé Jésù (F. Fajardo), Dec.
Mo Pinnu Pé Ọmọ Ogun Kristi Ni Màá Jẹ́ (D. Psarras), Apr.
Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN
Àbá Tí Àpọ́sítélì Pọ́ọ̀lù Fún Àwọn Atukọ̀ Òkun (Iṣe 27), No. 5
Àníyàn, No. 4
Báwo Ni Wọ́n Ṣe Ń Mú Iná Láti Ibì Kan dé Ibòmíì Láyé Àtijọ́? Jan.
Bí Gáyọ́sì Ṣe Ran Àwọn Ará Lọ́wọ́, May
Ẹ̀bùn Tó Dáa Ju Gbogbo Ẹ̀bùn Lọ, No. 6
Ẹlẹ́ṣin Mẹ́rin, No. 3
‘Ìbùkún Ni fún Ìlóyenínú Rẹ’ (Ábígẹ́lì), June
Ìjìyà, No. 1
Jósẹ́fù ará Arimatíà, Oct.
Kí Ni Amágẹ́dọ́nì? No. 6
Kí Nìdí Tí Jésù Fi Dẹ́bi fún Àwọn Tó Ń Búra? Oct.
Lẹ́tà Èdè Hébérù Tó Kéré Jù Lọ, No. 4
Ǹjẹ́ Àkókò Kan Ń Bọ̀ Tí Gbogbo Èèyàn Á Máa Ṣe Ìdájọ́ Òdodo? No. 3
Ohun Tí Bíbélì Sọ Nípa Ìyè àti Ikú, No. 4
“O Jẹ́ Obìnrin Kan Tí Ó Lẹ́wà ní Ìrísí” (Sárà), No. 3
Orúkọ Bíbélì Kan Tó Wà Lára Ìkòkò, Mar.
“Ó Ti Wu Ọlọ́run Dáadáa” (Énọ́kù), No. 1
Òwò Ẹrú, No. 2
Ọkàn Àwọn Èèyàn Ló Ṣe Pàtàkì, June
Ọlọ́run Pè É Ní “Ìyá Ọba” (Sárà), No. 5
Ṣé Àlááfíà Ṣì Máa Wà Láyé? No. 5
Ṣé Àwọn Áńgẹ́lì Wà Lóòótọ́? No. 5
Ṣé “Àwọn Ọjọ́ Ìkẹyìn” Là Ń Gbé Báyìí? No. 2
Ṣé Ayé Máa Di Párádísè Lóòótọ́? No. 4
Ṣé Lóòótọ́ La Lè Pe Àwọn Oníṣòwò Tó Ń Tajà Nínú Tẹ́ńpìlì Jerúsálẹ́mù Ní “Ọlọ́ṣà”? June
Tí Àìsàn Gbẹ̀mí-Gbẹ̀mí Bá Ń Ṣe Ẹni Tá A Nífẹ̀ẹ́, No. 4