Atọ́ka Àwọn Àkòrí Ilé Ìṣọ́ àti Jí! 2021
Ó ń tọ́ka sí ìwé ìròyìn tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde
ILÉ ÌṢỌ́—Ẹ̀DÀ TÓ WÀ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
ÀWA ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ
1921—Ní Ọgọ́rùn-ún Ọdún Sẹ́yìn, Oct.
ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
Bá A Ṣe Lè Máa Láyọ̀ Tá A Bá Ń Fara Da Ìṣòro, Feb.
Báwo La Ṣe Lè Tọ́ Oore Jèhófà Wò? Aug.
Báwo Ni Ìfẹ́ Jèhófà Tí Kì Í Yẹ̀ Ṣe Ń Ṣe Ọ́ Láǹfààní? Nov.
Bí Gbogbo Ìjọ Ṣe Lè Mú Kí Akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Kan Tẹ̀ Síwájú Kó sì Ṣèrìbọmi, Mar.
Bí Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run Ṣe Lè Mú Kó O Fara Da Ìṣòro, Mar.
“Èmi Yóò Mi Gbogbo Orílẹ̀-Èdè Jìgìjìgì” Sept.
Ẹ Di Ẹ̀kọ́ Òtítọ́ Tó Dá Yín Lójú Mú Ṣinṣin, Oct.
“Ẹ Gbọ́dọ̀ Jẹ́ Mímọ́,” Dec.
Ẹ Jẹ́ Kí Ìfẹ́ Tẹ́ Ẹ Ní fún Ara Yín Túbọ̀ Jinlẹ̀, Jan.
Ẹ Má Ṣe Jẹ́ Kó Rẹ̀ Yín! Oct.
Ẹ Má Ṣe Máa Bá Ara Yín Díje, Àlàáfíà Ni Kí Ẹ Máa Wá, July
Ẹ Máa ‘Fetí sí Jésù,’ Dec.
Ẹ Máa Fetí sí Ohùn Olùṣọ́ Àgùntàn Rere, Dec.
Ẹ Máa Fi Ìfẹ́ Tí Kì Í Yẹ̀ Hàn sí Ara Yín, Nov.
Ẹ̀yin Ọ̀dọ́kùnrin, Ẹ Ṣe Ohun Tó Máa Jẹ́ Káwọn Míì Fọkàn Tán Yín Mar.
Ẹ̀yin Tẹ́ Ẹ Ṣẹ̀ṣẹ̀ Ṣègbéyàwó, Ẹ Fi Ìgbésí Ayé Yín Ṣe Iṣẹ́ Ìsìn Jèhófà, Nov.
Fara Balẹ̀, Kó O sì Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà, Jan.
Fọkàn Balẹ̀, Jèhófà Wà Pẹ̀lú Rẹ, June
Ìfẹ́ Ń Jẹ́ Ká Lè Fara Da Ìkórìíra, Mar.
Jèhófà Máa Dáàbò Bò Ẹ́—Lọ́nà Wo? Mar.
Jèhófà Máa Fún Ẹ Lókun, May
Jẹ́ Kí Àǹfààní Iṣẹ́ Ìsìn Tó O Ní Máa Múnú Rẹ Dùn, Aug.
Jẹ́ Kí Ìfẹ́ Tó O Ní fún Jèhófà Àtàwọn Ará Túbọ̀ Jinlẹ̀, Sept.
Jẹ́ Kí Ìtẹ̀síwájú Rẹ Máa Múnú Rẹ Dùn! July
Jẹ́ Kó Túbọ̀ Dá Ẹ Lójú Pé Ẹlẹ́dàá Wà, Aug.
Kẹ́kọ̀ọ́ Lára “Ọmọ Ẹ̀yìn Tí Jésù Nífẹ̀ẹ́,” Jan.
Kí Ló Ń Fi Hàn Pé Ẹnì Kan Ti Ronú Pìwà Dà Tọkàntọkàn? Oct.
Kò Sí Ohun Tó Lè Mú Kí Olódodo Kọsẹ̀, May
Má Jẹ́ Kó Sú Ẹ Tó Bá Ṣòro Láti Wàásù Lágbègbè Yín, May
Má Ṣe Mú Kí “Àwọn Ẹni Kékeré Yìí” Kọsẹ̀ June
Máa Fi Hàn Pé O Mọyì Ìràpadà Nígbà Gbogbo, Apr.
Mọyì Àǹfààní Tó O Ní Pé O Wà Nínú Ìdílé Jèhófà, Aug.
Mọyì Àwọn Ọ̀dọ́ Tó Wà Nínú Ìjọ, Sept.
Mọyì Ipò Orí Tí Jèhófà Ṣètò Nínú Ìjọ, Feb.
Ǹjẹ́ O Mọyì Àwọn Àgbàlagbà Tó Wà Láàárín Wa, Sept.
Ogunlọ́gọ̀ Èèyàn ti Àgùntàn Mìíràn Ń Yin Jèhófà àti Kristi, Jan.
Ohun Tá A Rí Kọ́ Nínú Àwọn Ọ̀rọ̀ Tí Jésù Sọ Kẹ́yìn, Apr.
Ohun Tí Ìwé Léfítíkù Kọ́ Wa Nípa Bó Ṣe Yẹ Ká Máa Ṣe Sáwọn Èèyàn, Dec.
O Lè Bọ́ Lọ́wọ́ Ìdẹkùn Èṣù! June
O Lè Jẹ́ Olóòótọ́ Tí Èèyàn Ẹ Kan Bá Fi Jèhófà Sílẹ̀, Sept.
“Orí Gbogbo Ọkùnrin Ni Kristi” Feb.
“Orí Obìnrin Ni Ọkùnrin”Feb.
O Ṣeyebíye Gan-an Lójú Jèhófà! Apr.
Ọlọ́run “Tí Àánú Rẹ̀ Pọ̀” Là Ń Sìn, Oct.
Ran Àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Rẹ Lọ́wọ́ Kí Wọ́n Lè Ṣèrìbọmi, June
Ṣé Ìwọ Náà Lè Sọ Àwọn Èèyàn Di Ọmọ Ẹ̀yìn? July
Ṣé O Máa Ń Fara Dà Á Bíi Ti Jèhófà? July
Ṣé O Ní Ìgbàgbọ́ Tó Lágbára Tó? Nov.
Ṣé Wàá Dúró De Jèhófà? Aug.
Ṣé Wàá Jẹ́ Kí Ọ̀rọ̀ Nípa Jésù Mú Kó O Kọsẹ̀? May
“Tọ Ipasẹ̀ Rẹ̀ Pẹ́kípẹ́kí,” Apr.
BÍBÉLÌ
Báwo ni ọ̀rọ̀ tí wọ́n kọ sára òkúta kan láyé àtijọ́ ṣe fi hàn pé òótọ́ ni ọ̀rọ̀ inú Bíbélì? Jan.
ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ
Kí ni àpọ́sítélì Pọ́ọ̀lù ní lọ́kàn nígbà tó sọ pé: “Nípasẹ̀ òfin, mo ti di òkú sí òfin”? (Gál. 2:19), June
Kí ni òfin tó sọ pé ká má “dìde lòdì sí ẹ̀mí ẹnì kejì” wa túmọ̀ sí? (Léf. 19:16) Dec.
Kí nìdí tí Jésù fi sọ ohun tó wà nínú Sáàmù 22:1 ṣáájú ikú rẹ̀? Apr.
Kí nìdí tó fi yẹ káwa Kristẹni máa ṣọ́ra tá a bá ń lo àwọn ètò ìṣiṣẹ́ tí wọ́n fi ń fọ̀rọ̀ ránṣẹ́? Mar.
Ṣé ó yẹ káwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà máa lo ìkànnì àwọn tó ń wá ọkọ tàbí ìyàwó láti wá ẹni tá a máa fẹ́? July
ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI
ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ
A Pinnu Pé A Ò Ní Kọ Iṣẹ́ Tí Jèhófà Bá Fún Wa (K. Logan), Jan.
Jèhófà ‘Mú Kí Àwọn Ọ̀nà Mi Tọ́’ (S. Hardy), Feb.
Mo Gbádùn Ayé Mi Gan-an Lẹ́nu Iṣẹ́ Ìsìn Jèhófà (J. Kikot), July
“Mo Kẹ́kọ̀ọ́ Gan-an Lára Àwọn Míì!” (L. Breine), May
Mo Máa Ń Ro Ti Jèhófà Tí Mo Bá Ń Ṣèpinnu (D. Yazbek), June
Mò Ń Wá Bí Mo Ṣe Lè Gbé Ìgbé Ayé Tó Dáa (M. Witholt), Nov.
“Mo Ti Ń Gbádùn Iṣẹ́ Ìwàásù Báyìí!” (V. Vicini), Apr.
Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN
ILÉ ÌṢỌ́ TÁ À Ń FI SÓDE