Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀

Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀

Ṣé Bíbélì Wúlò Lóde Òní?

Tá a bá wo bí àwọn ẹ̀rọ ìgbàlódé ṣe mú kó rọrùn láti rí ìsọfúnni lóde òní, ṣé o rò pé Bíbélì ṣì wúlò fún wa? Bíbélì sọ pé:

“Gbogbo Ìwé Mímọ́ ni Ọlọ́run mí sí, ó sì ṣàǹfààní.”​—2 Tímótì 3:16.

Ìwé ìròyìn Ilé Ìṣọ́ yìí máa jẹ́ kó o mọ̀ bóyá lóòótọ́ ni Bíbélì lè tọ́ wa sọ́nà ní gbogbo apá ìgbésí ayé wa.