Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀

Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀

IBO LA TI LÈ RÍ ÌMỌ̀RÀN GIDI NÍPA BÁ A ṢE LÈ MÁA GBÉ ÌGBÉ AYÉ ALÁYỌ̀?

Bíbélì sọ pé: “Aláyọ̀ ni àwọn aláìní-àléébù ní ọ̀nà wọn.”​—Sáàmù 119:1.

Àwọn àpilẹ̀kọ méje yìí sọ àwọn ìlànà tó ṣeé gbára lé nípa bí èèyàn ṣe lè máa gbé ìgbé ayé aláyọ̀.