Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀
IBO LA TI LÈ RÍ ÌMỌ̀RÀN GIDI NÍPA BÁ A ṢE LÈ MÁA GBÉ ÌGBÉ AYÉ ALÁYỌ̀?
Bíbélì sọ pé: “Aláyọ̀ ni àwọn aláìní-àléébù ní ọ̀nà wọn.”—Sáàmù 119:1.
Àwọn àpilẹ̀kọ méje yìí sọ àwọn ìlànà tó ṣeé gbára lé nípa bí èèyàn ṣe lè máa gbé ìgbé ayé aláyọ̀.