Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Atọ́ka Kókó Àpilẹ̀kọ Fún Ilé Ìṣọ́ 2000

Atọ́ka Kókó Àpilẹ̀kọ Fún Ilé Ìṣọ́ 2000

Atọ́ka Kókó Àpilẹ̀kọ Fún Ilé Ìṣọ́ 2000

Ó ń tọ́ka sí ìtẹ̀jáde tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde

ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ

A Forí Lé Àwọn Erékùṣù Pàsífíìkì—Láti Lọ Ṣiṣẹ́! 8/15

A San Èrè fún Ìwákiri Ọlọ́jọ́ Pípẹ́ (Denmark), 9/1

A Tú Ìwé Dáníẹ́lì Palẹ̀! (ìwé Àsọtẹ́lẹ̀ Dáníẹ́lì), 1/15

Altiplano ní Peru, 11/15

“Àpẹẹrẹ Ìṣọ̀kan,” 10/15

Àwọn Ìlú Olókè ní Chiapas (Mẹ́síkò), 12/15

Àwọn Tó Ṣẹ̀ṣẹ̀ Di Mẹ́ńbà Ẹgbẹ́ Olùṣàkóso, 1/1

Ayẹyẹ Ìkẹ́kọ̀ọ́yege ní Gilead, 6/15, 12/15

Bí Wọn Ò Tiẹ̀ Ga, Wọ́n Lọ́kàn Tó Dára, 2/15

Erékùṣù Robinson Crusoe, 6/15

Fífi Ìwà Ọ̀làwọ́ Hàn Lọ́pọ̀ Yanturu Ń Máyọ̀ Wá (ọrẹ), 11/1

Ìjọba Násì Ń Pọ́n Wọn Lójú (Netherlands), 4/1

Íńdíà, 5/15

Ìpàdé Àgbègbè “Àwọn Olùṣe Ohun Tí Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run Wí,” 5/1

Ìpàdé Àgbègbè “Ọ̀rọ̀ Àsọtẹ́lẹ̀ Ọlọ́run,” 1/15

Ítálì, 1/15

Kíkéde Ìjọba ní Fíjì, 9/15

Pípẹja Ènìyàn Níbi Òkun Aegean, 4/15

Senegal, 3/15

Taiwan, 7/15

Tuvalu, 12/15

ÀWỌN OLÙPÒKÌKÍ ÌJỌBA RÒYÌN

2/1, 3/1, 4/1, 5/1, 6/1, 8/1, 9/1, 12/1

BÍBÉLÌ

Àwọn Ìwé Ìhìn Rere—Ṣé Ìtàn Gidi Ni Tàbí Àròsọ? 5/15

Ǹjẹ́ Àwọn Ọ̀rọ̀ Wà Tó Jẹ́ Ẹnà? 4/1

Ọdún Tí Èyí Táa Pín Kiri Pọ̀ Jù Lọ, 1/15

Ṣé Ìwé Tó Kàn Dára Ni? 12/1

ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ

Àwọn oògùn tí a mú jáde láti inú ẹ̀jẹ̀, 6/15

Ẹ̀jẹ̀ ara ẹni, 10/15

Ìrunú ta ni? (Ro 12:19), 3/15

Jèhófà ní inú dídùn sí títẹ Kristi rẹ́ kẹ̀? (Isa 53:10), 8/15

Kíkọ̀ láti tẹ́wọ́ gba ìgbésẹ̀ ìkọ̀sílẹ̀, 12/15

Ta ló ṣàròyé nípa òróró tẹ́nì kan dà sí Jésù lórí? 4/15

ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI

Àwọn Àpẹẹrẹ Rere—Jàǹfààní Lára Wọn, 7/1

Àwọn Ìgbéyàwó Aláyọ̀ Tí Ń Bọlá fún Jèhófà, 5/1

Báwo Lo Ṣe Ń Yanjú Aáwọ̀? 8/15

Dídámọ̀ràn Ara Rẹ Fáwọn Ẹlòmíràn, 4/15

Èé Ṣe Tó Fi Yẹ Ká Ní Ẹ̀mí Ìfara-Ẹni-Rúbọ? 9/15

Ẹ̀yin Kristẹni Olùṣọ́ Àgùntàn, ‘Ẹ Jẹ́ Kí Ọkàn-Àyà Yín Gbòòrò’! 7/1

Fi Ẹ̀mí Ìmúratán Sin Ọlọ́run, 11/15

“Fi Ìṣọ́ Ṣọ́ Ọkàn-Àyà Rẹ” (Òwe 4), 5/15

Fífi Ẹ̀mí Mímọ́ Ṣe Olùrànlọ́wọ́ Ara Ẹni, 10/15

Fífi Ọkàn-Àyà Táa Ti Múra Sílẹ̀ Wá Jèhófà, 3/1

Ìfojúsọ́nà Tó Mọ Níwọ̀n, 8/1

Ìmẹ̀tọ́mọ̀wà Ń Gbé Àlàáfíà Lárugẹ, 3/15

Ìmọ̀ràn Ọlọgbọ́n Látọ̀dọ̀ Ìyá Kan (Òwe 31), 2/1

Ìtùnú Nínú Okun Jèhófà, 4/15

Jẹ́ Oníwà Mímọ́ Nínú Ayé Oníṣekúṣe (Òwe 5), 7/15

Kí Ló Dé Tí Wọn Kò Bímọ? 8/1

Kí Lo Fi Ń Díwọ̀n Àṣeyọrí? 11/1

Kí Ló Ń Mú Ọ Sin Ọlọ́run? 12/15

Kí Ni Jíjẹ́ Kristẹni Túmọ̀ Sí? 6/1

Kòṣeémánìí Lètò Àjọ Jèhófà, 1/1

Má Ba Ara Rẹ Lórúkọ Jẹ́ (Òwe 6), 9/15

Ní Ìbárẹ́ Tímọ́tímọ́ Pẹ̀lú Jèhófà (Òwe 3), 1/15

O Ha Jẹ́ Olóye Bí? 10/1

Ojú Wo Lo Fi Ń Wo Ara Rẹ? 1/15

Orin Tí Ń Múnú Ọlọ́run Dùn, 6/1

Ọ̀wọ̀ Fáwọn Aláṣẹ, 8/1

‘Pa Àwọn Àṣẹ Mọ́ Kí O sì Máa Bá A Lọ Ní Wíwà Láàyè’ (Òwe 7), 11/15

Sísún Mọ́ Ọlọ́run, 10/15

Ṣé O Ti Di “Géńdé” Kristẹni? 8/15

Ṣé Ojú Tí Ọlọ́run Fi Ń Wo Àwọn Oníwà Ipá Lo Fi Ń Wò Wọ́n? 4/15

ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ

Àìwalé-Ayé-Máyà Ló Jẹ́ Kí N Lè Sin Jèhófà (C. Moyer), 3/1

Atànmọ́lẹ̀ fún Ọ̀pọ̀ Orílẹ̀-Èdè (G. Young), 7/1

Dídúpẹ́ Lọ́wọ́ Jèhófà—Nípa Ṣíṣe Iṣẹ́ Ìsìn Alákòókò Kíkún! (S. Reynolds), 5/1

“Ẹ Kan Sáárá sí Ìgbàgbọ́ Kan Tí Kì Í Yẹ̀”! (H. Müller), 11/1

“Ẹ Kò Mọ Ohun Tí Ìwàláàyè Yín Yóò Jẹ́ Lọ́la” (H. Jennings), 12/1

Jèhófà Máa Ń San Èrè fún Àwọn Ìránṣẹ́ Rẹ̀ Adúróṣinṣin (V. Duncombe), 9/1

Jèhófà Ni Ààbò àti Okun Mi (M. Filteau), 2/1

Mo Rí Ogún Àkànṣe Gbà (C. Allen), 10/1

Olùṣe Ohun Ìjà Tẹ́lẹ̀ Wá Di Olùgba Ẹ̀mí Là (I. Ismailidis), 8/1

Ó Ràn Mí Lọ́wọ́ Láti Borí Ìtìjú (R. Ulrich), 6/1

Rírántí Ẹlẹ́dàá Láti Ìgbà Èwe (D. Hibshman), 1/1

JÈHÓFÀ

Báwo Lo Ṣe Fẹ́ Kí Ó Rántí Rẹ? 2/1

Máa Ń Gbọ́ Àdúrà, 3/1

Tóbi Ju Ọkàn-Àyà Wa Lọ, 5/1

JÉSÙ KRISTI

Bí Jésù Kristi Ṣe Lè Ràn Wá Lọ́wọ́, 3/15

LÁJORÍ ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

“Arákùnrin Ni Gbogbo Yín,” 6/15

Àwọn Ẹbọ Ìyìn Tí Inú Jèhófà Dùn Sí, 8/15

Àwọn Ẹbọ Tí Inú Ọlọ́run Dùn Sí, 8/15

“Àwọn Ohun Fífani-Lọ́kàn-Mọ́ra” Ń Kún Ilé Jèhófà, 1/15

Àwọn Tí Ń Bá Ọlọ́run Jà Kò Ní Borí, 4/1

Àwọn Wo Ni Òjíṣẹ́ Ọlọ́run Lóde Òní? 11/15

Ayé Tuntun Náà—Ṣé Wàá Wà Níbẹ̀? 4/15

Báwo Ni Àkókò Tó Ṣẹ́ Kù fún Àwọn Olubi Ti Pọ̀ Tó? 2/1

Bíbá Olùṣọ́ Náà Ṣiṣẹ́ Pọ̀, 1/1

Bíbélì Kíkà—Ó Lérè, Ó sì Gbádùn Mọ́ni, 10/1

Bí Jèhófà Ṣe Ń Ṣamọ̀nà Wa, 3/15

Di Ẹ̀kọ́ Ọlọ́run Mú Gírígírí, 5/1

Ẹ Dúró Lọ́nà Pípé Pẹ̀lú Ìgbàgbọ́ Tó Fìdí Múlẹ̀, 12/15

Ẹ Fi Ẹ̀mí Ìdúródeni Hàn! 9/1

“Ẹ Máa Bá A Nìṣó Ní Ṣíṣọ́nà,” 1/15

Ẹ Máa Bọlá fún Àwọn Tó Ní Ọlá Àṣẹ Lórí Yín, 6/15

“Ẹ Máa Wá Jèhófà àti Okun Rẹ̀,” 3/1

Ẹ Ní Ẹ̀mí Ìrònú Kristi, 9/1

Ẹ Ní Ìgbàgbọ́ Nínú Ọ̀rọ̀ Àsọtẹ́lẹ̀ Ọlọ́run! 5/15

“Ẹni Tí Ó Kéré” Ti Di “Ẹgbẹ̀rún,” 1/1

Fífúnrúgbìn Òtítọ́ Ìjọba Náà, 7/1

‘Gba Ara Rẹ Àtàwọn Tí Ń Fetí sí Ọ Là,’ 6/1

Gbọ́ Ohun Tí Ẹ̀mí Ní Í Sọ, 5/1

Ìjọba Ọlọ́run—Ìṣàkóso Tuntun fún Ilẹ̀ Ayé, 10/15

Ìkùgbù Máa Ń Fa Àbùkù, 8/1

Ìrètí Àjíǹde Dájú! 7/15

Ìrètí Àjíǹde Lágbára, 7/15

Iṣẹ́ Ìsìn Ń Fún Àwọn Kristẹni Láyọ̀, 11/15

Jèhófà—Alágbára Ńlá, 3/1

Jèhófà Kò Ní Fi Nǹkan Falẹ̀, 2/1

Jèhófà Ń Fi Agbára fún Ẹni Tó Ti Rẹ̀, 12/1

Jẹ́ Kí “Ìrètí Ìgbàlà” Wà Lọ́kàn Rẹ Digbí! 6/1

Kíkẹ́kọ̀ọ́—Ó Ṣàǹfààní, Ó sì Gbádùn Mọ́ni, 10/1

Kíkún fún Ìdùnnú Nínú Ọlọ́run Ìgbàlà Wa, 2/1

Máa Fi Ìháragàgà Polongo Ìhìn Rere Náà, 7/1

Máa Fiyè sí Ọ̀rọ̀ Àsọtẹ́lẹ̀ Ọlọ́run, 4/1

Máa Fiyè sí Ọ̀rọ̀ Àsọtẹ́lẹ̀ Ọlọ́run fún Ọjọ́ Wa, 5/15

Mímọ “Èrò Inú Kristi,” 2/15

Ǹjẹ́ A Sún Ọ Láti Ṣe Bíi Ti Jésù? 2/15

Ǹjẹ́ O Ní “Èrò Inú Kristi”? 2/15

Ǹjẹ́ O Nífẹ̀ẹ́ Àwọn Ìránnilétí Jèhófà Lọ́nà Tó Kọyọyọ? 12/1

Ogún Wa Ṣíṣeyebíye—Kí Ló Túmọ̀ sí fún Ọ? 9/1

Ohun Tí Ìjọba Ọlọ́run Yóò Ṣe, 10/15

Ojú Tí Ọlọ́run Fi Ń Wo Ìwà Mímọ́, 11/1

O Lè Máa Bá Híhùwà Mímọ́ Nìṣó, 11/1

“Ọgbọ́n Wà Pẹ̀lú Àwọn Amẹ̀tọ́mọ̀wà,” 8/1

‘Ọlọ́run, Rán Ìmọ́lẹ̀ Rẹ Jáde,’ 3/15

Ran Àwọn Ẹlòmíràn Lọ́wọ́ Láti Rìn Lọ́nà Tó Yẹ Jèhófà, 12/15

Ríra Àkókò Padà Láti Kàwé àti Láti Kẹ́kọ̀ọ́, 10/1

Sísọ Ohun Gbogbo Di Tuntun—Bí A Ti Sọ Ọ́ Tẹ́lẹ̀, 4/15

“Wákàtí Náà Ti Dé!” 9/15

“Wákàtí Rẹ̀ Kò Tíì Dé,” 9/15

Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN

Àjẹ́ Ṣíṣe, 4/1

Àlàáfíà Ayé—Lọ́nà Wo? 11/1

Áńtíókù (Síríà), 7/15

Àṣírí Àṣeyọrí, 2/1

“Àwọn Àkókò Ìmúpadàbọ̀sípò” Ti Kù sí Dẹ̀dẹ̀! 9/1

Àwọn Alárìíwísí, 7/15

“Àwọn Ará ní Poland,” 1/1

Àwọn Ohun Tí Wọ́n Rí ní Jésíréélì, 3/1

Ayé Téèyàn Ò Ti Ní Bọ́hùn Mọ́, 9/15

Bí Ẹ̀mí Ṣe Ń Ṣiṣẹ́ Lónìí, 4/1

Bí O Ṣe Lè Ní Ọ̀rẹ́, 12/1

Cyril Lucaris—Ọkùnrin Tó Mọyì Bíbélì, 2/15

Èé Ṣe Tó Fi Yẹ Ká Borí Ẹ̀mí Ìṣefínnífínní Dóríi Bíńtín? 6/15

“Ewúrẹ́ Olóòfà Ẹwà Ti Orí Òkè Ńlá,” 10/1

Ẹwà Inú Lọ́hùn-ún, 11/15

Gbígbógun Ti Ìwà Ìbàjẹ́, 5/1

Ibi Tóo Ti Lè Rí Ìmọ̀ràn Rere Gbà, 6/1

Igi Ólífì, 5/15

Ìgbàgbọ́ Lè Yí Ìgbésí Ayé Rẹ Padà, 1/1

Ìgbésí Ayé Lè Túbọ̀ Nítumọ̀, 7/15

Ìkórìíra, Dópin Kẹ̀? 8/15

Ìṣọ̀kan Ìsìn Ha Sún Mọ́lé Bí? 12/1

Ìwàláàyè Lẹ́yìn Ikú, 10/1

Ìwàláàyè Pípé—Kì Í Màá Ṣe Àlá Lásán! 6/15

Jòsáyà, 9/15

Kíkẹ́kọ̀ọ́ Lára Tọkọtaya Ẹ̀dá Ènìyàn Àkọ́kọ́, 11/15

Máa Kọbi Ara sí Ìkìlọ̀! 2/15

Ǹjẹ́ Àṣà Kérésìmesì Bá Ìsìn Kristẹni Mu? 12/15

Ǹjẹ́ Ìwà Rere Tí Bíbélì Fi Kọ́ni Ṣeé Fi Sílò? 11/1

Ǹjẹ́ O Máa Ń Gba Ohun Tí O Kò Lè Rí Gbọ́? 6/15

Ǹjẹ́ O Mọ Bí A Ṣe Ń Dúró De Nǹkan? 9/1

Ǹjẹ́ Ó Tiẹ̀ Láǹfààní Tádùúrà Gbígbà Ń Ṣe? 11/15

Onínúnibíni Rí Ìmọ́lẹ̀ Ńlá (Pọ́ọ̀lù), 1/15

Ọkùnrin Àwòfiṣàpẹẹrẹ Kan Tó Tẹ́wọ́ Gba Ìbáwí (Jóòbù), 3/15

Ọlọ́run Máa Ń Gbọ́ Àdúrà, 3/1

“Rìn Yí Ká Pẹpẹ Rẹ,” 5/1

Rírí Ìbàlẹ̀ Ọkàn, 7/1

Ṣàyẹ̀wò Àwọn Ẹ̀sìn Mìíràn Kẹ̀? 10/15

Ṣé Dandan Ni Kí O Gbà Á Gbọ́? 12/1

Ṣíṣiṣẹ́ Nínú “Pápá”—Ṣáájú Ìkórè, 10/15