Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ 2001
Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ 2001
Ó ń tọ́ka sí ìtẹ̀jáde tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde
ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ
A Kò Nìkan Wà Nígbà Táa Dán Ìgbàgbọ́ Wa Wò (ẹ̀jẹ̀), 4/15
A Ń Sa Gbogbo Ipá Wa! (àwọn míṣọ́nnárì) 10/15
Àpéjọpọ̀ “Àwọn Olùkọ́ni Ní Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run,” 5/1
Àpéjọpọ̀ “Àwọn Olùṣe Ohun Tí Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run Wí,” 1/15
Àwọn Àpéjọpọ̀—Àkókò Aláyọ̀ fún Ẹgbẹ́ Àwọn Ará, 9/15
Bíborí Inúnibíni Ìjọba Násì, 3/15
Ẹgbẹ́ Olùṣàkóso àti Àjọ Táa Fòfin Gbé Kalẹ̀, 1/15
Ìgbà Kan Wà Táa Jẹ́ Ìkookò—A Ti Di Àgùntàn Báyìí! 9/1
Ìkẹ́kọ̀ọ́yege ní Gílíádì, 6/15, 12/15
Ilẹ̀ Faransé, 8/15, 9/1
“Ìpàdé Di Inú Ìjọba Ọlọ́run” (F. Drozg), 11/15
Ìpàdé Ọdọọdún ti Ọdún 2000, 1/15
“Iṣẹ́ Àgbàyanu Kan” (Photo-Drama [Àwòkẹ́kọ̀ọ́ Onífọ́tò]), 1/15
Ìwé Ẹ̀rí Ìgbóríyìnfúnni (Kóńgò [Kinshasa]), 8/15
Jíjàre ní Kóòtù Tí Ń Rí Sọ́ràn Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn (Jámánì), 8/15
‘Ká Dúpẹ́ Lọ́wọ́ Àwọn Ẹlẹ́rìí Nítorí Òmìnira Ìsìn,’ 5/15
Kẹ́ńyà, 2/15
Ó Ha Lè Jẹ́ Iṣẹ́ Tó Dára Jù Lọ fún Ọ? (Iṣẹ́ Ìsìn Bẹ́tẹ́lì), 3/15
Omi Tí Ń Fúnni Ní Ìyè Ń Ṣàn Láwọn Òkè Andes, 10/15
Oníṣègùn Ojú Gbin Irúgbìn (Ukraine, Israel), 2/1
“Ọjọ́ Ìfàyègba Ẹ̀sìn Mìíràn” (iléèwé Poland), 11/1
Ríran Àwọn Ọ̀dọ́ Lọ́wọ́, 7/15
Wọ́n Bìkítà fún Ara Wọn (àwọn tí ogun sọ di olùwá-ibi-ìsádi), 4/15
ÀWỌN OLÙPÒKÌKÍ ÌJỌBA RÒYÌN
2/1, 4/1, 5/1, 6/1, 8/1, 10/1, 12/1
BÍBÉLÌ
Àwọn Àkájọ Ìwé Òkun Òkú, 2/15
Àwọn Èèyàn Mọyì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun, 11/15
Bíbélì Wà Ní Ìdìpọ̀ Kan Ṣoṣo, 5/1
Cyril àti Methodius—Àwọn Olùtumọ̀, 3/1
Èé Ṣe Tó Fi Yẹ Ká Kẹ́kọ̀ọ́ Rẹ̀? 7/1
Lílóye Bíbélì, 7/1
ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ
Àwọn ọ̀pá tá a fi ń gbé àpótí májẹ̀mú (1Ọb 8:8), 10/15
Báwo la ṣe dá ohun gbogbo “fún” Jésù? (Kól 1:16), 9/1
Báwo ni àkókò tí Jóòbù fi jìyà ṣe gùn tó? 8/15
Báwo ni ejò ṣe bá Éfà sọ̀rọ̀? 11/15
Èé ṣe tó fi yẹ ká jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ fáwọn alàgbà? 6/1
Fífúnni ní àkójọ ìlànà tí kọ̀ǹpútà fi ń ṣiṣẹ́, 2/15
Ibo ni Dáníẹ́lì wà nígbà àdánwò ère oníwúrà? (Dá 3), 8/1
“Ìbọ̀rìṣà tí ó lòdì sí òfin” (1Pé 4:3), 7/15
Ìgbà wo la fòróró yan “Ibi Mímọ́ nínú Àwọn Ibi Mímọ́”? (Dá 9:24), 5/15
Ìtumọ̀ sísìn “ní ẹ̀mí” (Jò 4:24), 9/15
Kristẹni aya àti àwọn ọdún, 12/15
Ṣé ó yẹ ká gbàdúrà nípa ẹni tá a yọ lẹ́gbẹ́? (Jer 7:16), 12/1
Ṣé Úrì ni Jèhófà ti bá Ábúráhámù dá májẹ̀mú tàbí Háránì? 11/1
Wíwọnú ìsinmi Jèhófà (Héb 4:9-11), 10/1
ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI
“Aláyọ̀ Ni Ènìyàn Tí Ó Ti Wá Ọgbọ́n Rí” (Òwe 8), 3/15
Àwọn Àṣà, 8/1
Bíborí Èrò Òdì, 4/15
Borí Àwọn Ohun Tó Lè Dènà Ìtẹ̀síwájú, 8/1
Dáàbò Bo Ẹ̀rí Ọkàn Rẹ, 11/1
Ẹ fún Àwọn Ọmọ Yín Lóhun Tí Wọ́n Nílò! 12/15
Ẹ Máa Bójú Tó Àwọn Ọmọ Òrukàn Àtàwọn Opó, 6/15
“Ẹ Sáré Ní Irúfẹ́ Ọ̀nà Bẹ́ẹ̀,” 1/1
Fífún Ìgbẹ́kẹ̀lé Nínú Jèhófà Lókun, 6/1
‘Ìbùkún Jèhófà Ní Í Sọni Di Ọlọ́rọ̀,’ 11/1
‘Ìbùkún Wà fún Olódodo’ (Òwe 10), 7/15
Ìdúróṣinṣin, 10/1
Ìgbọràn—Ẹ̀kọ́ Pàtàkì Téèyàn Ń Kọ́ Lọ́mọdé, 4/1
Ìjẹ́wọ́, 6/1
Iyèméjì, 7/1
Kíkẹ́sẹ Járí Láìka Bí Wọ́n Ṣe Tọ́ni Dàgbà Sí, 4/15
Máa Rìn Ní ‘Ipa Ọ̀nà Ìdúróṣánṣán’ (Òwe 10), 9/15
Ní Ìwà Funfun, 1/15
‘Nípasẹ̀ Ọgbọ́n Ni Ọjọ́ Wa Yóò Fi Di Púpọ̀’ (Òwe 9), 5/15
Ǹjẹ́ Ó Máa Ń Dà Bíi Pé Wọ́n Ṣì Ọ́ Lóye? 4/1
Ojú Tá A Fi Ń Wo Ìwà Àgàbàgebè, 11/15
O Mà Lè Borí Ìrẹ̀wẹ̀sì! 2/1
Ríran Àwọn Opó Lọ́wọ́, 5/1
Ṣé Lóòótọ́ Ni Ò Ń Rára Gba Nǹkan? 7/15
Ṣíṣe Àwọn Ìpinnu Tó Mọ́gbọ́n Dání, 9/1
Yẹra fún Àrùn Ọkàn Nípa Tẹ̀mí, 12/1
ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ
A Dán Jèhófà Wò (P. Scribner), 7/1
Ayọ̀ Mi Kún, Ẹnu Mi Ò Sì Gbọpẹ́, Láìka Àdánù Ńláǹlà Sí (N. Porter), 6/1
Dídúpẹ́ fún Àwọn Ìrírí Mánigbàgbé! (D. Caine), 8/1
Ìgbésí Ayé Alárinrin Nínú Iṣẹ́ Ìsìn Jèhófà (R. Kurzen), 11/1
Ìmọ́lẹ̀ Ti Tàn ní Àárín Gbùngbùn Ìlà Oòrùn (N. Salem), 9/1
Jèhófà Mẹ́sẹ̀ Mi Dúró (F. Lee), 3/1
Ó “Fara Dà Á Dé Òpin” (L. Swingle), 7/1
Ohun Ìyanu Lọ́tùn-ún Lósì (E. & H. Beveridge), 10/1
“Oore Tí Jèhófà Ṣe fún Mi Mà Pọ̀ O!” (K. Klein), 5/1
Òṣùṣù Ọwọ̀ Ni Wá (M. Barry), 4/1
Sísìn Níbikíbi Tí A Bá Ti Nílò Mi (J. Berry), 2/1
Sísìn Tọkàntọkàn Lójú Onírúurú Àdánwò (R. Lozano), 1/1
Títẹ̀síwájú Lọ́nà Jèhófà (L. Valentino), 5/1
Títẹ́wọ́gba Ìkésíni Látọ̀dọ̀ Jèhófà (M. Zanardi), 12/1
JÈHÓFÀ
Fífún Ìgbẹ́kẹ̀lé Nínú Rẹ̀ Lókun, 6/1
‘Ìbùkún Rẹ̀ Ń Sọni Di Ọlọ́rọ̀,’ 11/1
JÉSÙ KRISTI
Àjíǹde, 3/15
Ẹni Náà Gan-an Tí A Ń Pè Ní Jésù, 12/15
Jésù Ń Gbani Là—Lọ́nà Wo? 11/15
LÁJORÍ ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
Ábúráhámù—Àpẹẹrẹ Ìgbàgbọ́, 8/15
Àwọn Alábòójútó àti Ìránṣẹ́ Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Táa Yàn Sípò Lọ́nà Ìṣàkóso Ọlọ́run, 1/15
Àwọn Ènìyàn Jèhófà Tí A Mú Bọ̀ Sípò Ń Yìn Ín Jákèjádò Ayé, 2/15
Ayọ̀ Yíyọ̀ Fáwọn Tí Ń Rìn Nínú Ìmọ́lẹ̀, 3/1
Báwo Lo Ṣe Lè Ran Ọmọ “Onínàákúnàá” Lọ́wọ́? 10/1
Báwo Ni Àlàáfíà Kristi Ṣe Lè Máa Ṣàkóso Nínú Ọkàn-Àyà Wa? 9/1
Báwo Ní Ìfẹ́ Rẹ Ṣe Gbòòrò Tó? 1/1
Bẹ̀rù Jèhófà, Kí O sì Pa Àwọn Àṣẹ Rẹ̀ Mọ́, 12/1
Bíborí Àìpé Ẹ̀dá, 3/15
“Bí Ọlọ́run Bá Wà fún Wa, Ta Ni Yóò Wà Lòdì sí Wa?” 6/1
‘Ẹ Fi Ìpamọ́ra Wọ Ara Yín Láṣọ,’ 11/1
Ẹ Jẹ́ Òjíṣẹ́ Tí Ń Fi Tayọ̀tayọ̀ Kórè! 7/15
‘Ẹ Kẹ́kọ̀ọ́ Lọ́dọ̀ Mi,’ 12/15
Ẹ Máa Bá A Lọ Ní Fífẹsẹ̀múlẹ̀ Ṣinṣin Bí Ẹni Tí Ń Rí Ẹni Tí A Kò Lè Rí! 6/15
Ẹ Máa Bá Iṣẹ́ Ìkórè Náà Lọ Ní Rabidun! 7/15
Ẹ Máa Yọ̀ Nínú Ìmọ̀ Jèhófà, 7/1
Ẹ Máa Yọ̀ Nínú Iṣẹ́ Ìsìn Jèhófà, 5/1
Ẹ Máa Yọ̀ Pẹ̀lú Ọlọ́run Aláyọ̀, 5/1
Ẹ Má Ṣe Di Olùgbọ́ Tí Ń Gbàgbé, 6/15
Ẹ Má Ṣe Juwọ́ Sílẹ̀ Ní Ṣíṣe Ohun Tó Dára, 8/15
Ẹ Wá Jèhófà Kí Ọjọ́ Ìbínú Rẹ̀ Tó Dé, 2/15
Ẹ Wá Wo Olùṣe Àwọn Ohun Àgbàyanu! 4/15
Ẹ Yin Jèhófà Nítorí Àwọn Iṣẹ́ Àrà Rẹ̀! 5/15
Fara Wé Jèhófà Nígbà Tóo Bá Ń Tọ́ Àwọn Ọmọ Rẹ, 10/1
Fiyè sí Àwọn Iṣẹ́ Àgbàyanu Ọlọ́run, 4/15
Gbé Èrò Inú Rẹ Ka Ẹ̀mí, Kí O sì Yè! 3/15
Gbígbé Ìdílé Tó Dúró Sán-ún Nípa Tẹ̀mí Ró, 5/15
Ìbùkún Jèhófà Ní Í Sọ Wá Dọlọ́rọ̀, 9/15
Ìbùkún Jèhófà Yóò Ha Dé Bá Ọ Bí? 9/15
Ìgbàlà Fáwọn Tó Yan Ìmọ́lẹ̀, 3/1
Ìsìn Kristẹni Tòótọ́ Ti Borí! 4/1
Ìtọ́sọ́nà Ọlọ́run Lórí Ọ̀ràn Yíyan Ẹni Tí A Óò Fẹ́, 5/15
Jèhófà Jẹ́ Ọlọ́run Onípamọ́ra, 11/1
Jèhófà Ń Fi Bí A Ó Ṣe Máa Ka Àwọn Ọjọ́ Wa Hàn Wá, 11/15
Jèhófà Ni Ibi Ìsádi Wa, 11/15
Jẹ́ Kí Ìbẹ̀rù Jèhófà Wà ní Ọkàn Rẹ, 12/1
Jẹ́ Kí Ìlọsíwájú Rẹ Fara Hàn Kedere, 8/1
Kí Ìfẹ́ Máa Gbé Yín Ró, 1/1
Máa Bá Ètò Àjọ Jèhófà Rìn, 1/15
“Máa Wá Àlàáfíà, Kí O sì Máa Lépa Rẹ̀,” 9/1
Ní Irú Ìgbàgbọ́ Tí Ábúráhámù Ní! 8/15
Ní Ọkàn-Àyà Tó Tẹ́ Jèhófà Lọ́rùn, 10/15
Nípìn-ín Nínú Ayọ̀ Tó Wà Nínú Fífúnni! 7/1
Ǹjẹ́ O Lè “Fi Ìyàtọ̀ Sáàárín Ohun Tí Ó Tọ́ àti Ohun Tí Kò Tọ́”? 8/1
Ǹjẹ́ Ò Ń Gbé Níbàámu Pẹ̀lú Ìyàsímímọ́ Rẹ? 2/1
Ǹjẹ́ O Ti Sọ Òtítọ́ Di Tìrẹ? 2/1
Oògùn Ajẹ́bíidán fún Másùnmáwo, 12/15
Ọjọ́ Ìdájọ́ Jèhófà Ti Sún Mọ́lé! 2/15
“Ọ̀rọ̀ Jèhófà Ń Bá A Lọ Ní Gbígbilẹ̀,” 4/1
Pa Ọkàn-Àyà Rẹ Mọ́! 10/15
Ta Ni Yóò Yà Wá Kúrò Nínú Ìfẹ́ Ọlọ́run? 10/15
Títẹ̀síwájú sí Ìṣẹ́gun Ìkẹyìn! 6/1
Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN
Ààbò Nínú Ayé Eléwu, 2/1
“Amúniláradá fún Ìdodo Rẹ,” 2/1
Àwọn Bàbá Ìjọ—Ṣé Alágbàwí Òtítọ́ Ni Wọ́n? 4/15
Àwọn Hasmonaean, 6/15
Àwọn Igi Tó Rọ́kú, 7/1
Àwọn Ohun Tó Ń Pagi Run, 11/1
Àwọn Ọgbẹ́ Ogun, 1/1
Ayọ̀, 3/1
Bí Ìgbà Èwe Ṣe Lè Dùn Bí Oyin, 8/15
Énọ́kù Bá Ọlọ́run Rìn, 9/15
Èrò Tó Wà Níwọ̀ntúnwọ̀nsì Nípa Owó, 6/15
Èṣù, 9/1
“Ewu Tó Dojú Kọ Ìlera Gbogbo Ènìyàn,” (Ohun arùfẹ́-ìṣekúṣe-sókè lórí Íńtánẹ́ẹ̀tì), 4/15
Ẹ̀kọ́ Táa Lè Rí Kọ́ Lára Igi Ọ̀pẹ, 10/1
‘Ẹ Wò Ó! Ogunlọ́gọ̀ Ńlá Náà!’ 5/15
Ìbẹ́mìílò, 5/1
Ìdí fún Ohun Tóo Gbà Gbọ́, 8/1
Ìgbàgbọ́ Nóà Dá Ayé Lẹ́bi, 11/15
Ìhìn Rere Ìjọba Náà, 4/1
Ìlànà Ta Ni O Lè Gbẹ́kẹ̀ Lé? 6/1
Iṣẹ́ Abẹ Láìlo Ẹ̀jẹ̀, 3/1
Ìyà, 5/15
Kí Ló Níye Lórí Jù Lọ? 9/15
Máa Dúpẹ́, Kóo sì Máa Yọ̀, 9/1
“Mo Ké Gbàjarè sí Késárì!” 12/15
“Nípasẹ̀ Ìmọ́lẹ̀ Láti Ọ̀dọ̀ Rẹ Ni Àwa Fi Lè Rí Ìmọ́lẹ̀,”12/1
Ǹjẹ́ Ẹ̀mí Èèyàn Máa Ń Kú? 7/15
Ǹjẹ́ Nǹkan Kan Tiẹ̀ Wà Tó Lè So Aráyé Pọ̀ Ṣọ̀kan? 9/15
Ǹjẹ́ O Lè Tún Ayé Ṣe? 10/15
Òfin Pàtàkì Náà Ṣì Bóde Mu, 12/1
Ó Lálòpẹ́ Ju Ògidì Wúrà Lọ, 8/1
O Lè Ní Ìgbàgbọ́ Tòótọ́, 10/1
“Oògùn Ojú Láti Fi Pa Ojú Rẹ,” 12/15
Origen—Bí Ẹ̀kọ́ Rẹ̀ Ṣe Nípa Lórí Ṣọ́ọ̀ṣì, 7/15
Párádísè Tẹ̀mí, 3/1
Pọ́ọ̀lù Ṣètò Ọrẹ Àfiṣèrànwọ́ Fáwọn Ẹni Mímọ́, 3/15
Síkítíánì, 11/15
Ṣé Èèyàn Máa Ń Wà Láàyè Lẹ́yìn Ikú? 7/15