Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ 2002
Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ 2002
Ó ń tọ́ka sí ìtẹ̀jáde tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde
ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ
Akitiyan Tó Ń Gbé Ìlànà Ìwà Rere Ga (Mòsáńbíìkì), 11/15
Àpéjọ Àgbáyé Yóò Wáyé Lọ́dún 2003, 7/1
Àpéjọ “Àwọn Olùkọ́ni ní Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run,” 1/15
A Ṣí Àwọn Gbọ̀ngàn Ìjọba Sílẹ̀ fún Gbogbo Èèyàn Láti Wò, 11/1
Àwọn Ajẹ́rìíkú Òde Òní (Sweden), 2/1
Àwọn Alátìlẹyìn Ìjọsìn Tòótọ́ (ọrẹ), 11/1
Àwọn Èwe Tó Ń Tuni Lára, 9/15
Àwọn Ìpàdé, 3/15
Àwọn Òkè Ńlá Philippines, 4/15
Àwọn Orílẹ̀-Èdè Balkan (Ìtumọ̀ Ayé Tuntun), 10/15
Àwọn Ọ̀dọ́ Tó Fẹ́ràn Òtítọ́, 10/1
Àwọn Pásítọ̀ Tó Mọyì Àwọn Ìwé Tí Russell Kọ, 4/15
Ayẹyẹ Ìkẹ́kọ̀ọ́yege ní Gílíádì, 6/15, 12/15
Bí Ọmọ Kan Ṣe Ran Bàbá Rẹ̀ Lọ́wọ́, 5/1
Gbọ̀ngàn Ìjọba Kan Gba Àmì Ẹ̀yẹ (Finland), 10/1
Ìbísí Bíbùáyà Mú Kí Ìmúgbòòrò Pọn Dandan (Àwọn Gbọ̀ngàn Ìjọba), 5/15
“Ìdí Tí Mo Fi Dá Owó Yín Padà,” 8/15
‘Ìfẹ́ Wa Ti Jinlẹ̀ Sí I’ (òkè ayọnáyèéfín ní Japan), 3/1
Ìpàdé Ọdọọdún ti 2001, 4/1
Iṣẹ́ Àtàtà Ń Yin Ọlọ́run Lógo (Ítálì), 1/15
Kí Ló Gbà Láti Ní Ẹ̀rí Ọkàn Mímọ́? 2/15
Lórí Tábìlì Ọ̀gákọ̀ (R. G. Smith), 12/1
“Máa Ṣe Ohun Rere sí Gbogbo Ènìyàn,” 7/15
Ọmọdé Gbọ́n, Àgbà Gbọ́n (àwọn ọmọdé tó ń dáwó), 2/1
Wọ́n Ti Mọ̀wé Kà (Solomon Islands), 8/15
ÀWỌN OLÙPÒKÌKÍ ÌJỌBA RÒYÌN
2/1, 4/1, 6/1, 8/1, 10/1, 11/1
BÍBÉLÌ
Akitiyan Láti Tẹ Bíbélì Lédè Gíríìkì Òde Òní, 11/15
Ìtumọ̀ Septuagint, 9/15
Ọba Henry Kẹjọ àti Bíbélì, 1/1
ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ
Àánú Jèhófà ń pẹ̀rọ̀ sí ìdájọ́ òdodo rẹ̀ kẹ̀? 3/1
Àgbàlá níbi tí “ogunlọ́gọ̀ ńlá” ti ń sìn (Ìṣí 7:15), 5/1
Àwọn ìgbà wo ló yẹ kí Kristẹni obìnrin borí rẹ̀? 7/15
Gbígbàdúrà láìsọ pé “ní orúkọ Jésù,” 4/15
Ìgbéyàwó láàárín àwọn ìbátan, 2/1
Ìtumọ̀ “dúró títí dé orí ẹ̀jẹ̀” (Héb 12:4), 2/15
Iye àwọn ọmọ Jésè (1 Sa 16:10, 11; 1 Kr 2:13-15), 9/15
Lúsíférì (Isa 14:12, KJ), 9/15
Ǹjẹ́ àìpé Màríà ran Jésù? 3/15
Ǹjẹ́ Ébẹ́lì mọ̀ pé ó pọ̀n dandan láti fi ẹran rúbọ? 8/1
Ǹjẹ́ ó bójú mu láti lọ sọ ọ̀rọ̀ ìsìnkú ẹni tó pa ara rẹ̀? 6/15
Ǹjẹ́ ó bọ́gbọ́n mu láti lọ bá wọn ṣètò ìsìnkú tàbí ìgbéyàwó nínú ṣọ́ọ̀ṣì? 5/15
Ǹjẹ́ ó lòdì láti kọ́ iyàn tí owó rẹ̀ kò jù táṣẹ́rẹ́? 11/1
Ọmọ títọ́ nínú ilé tí ìsìn ti yàtọ̀ síra, 8/15
Ṣé dandan ni ká ri aláàbọ̀ ara tàbí ẹni tí ipò rẹ̀ gbẹgẹ́ gan-an bọmi pátápátá? 6/1
Ṣé gbogbo ìgbà la gbọ́dọ̀ san ẹ̀jẹ́ tá a bá jẹ́ fún Ọlọ́run? 11/15
Ṣe ọ̀pọ̀ rẹpẹtẹ la máa tàn jẹ nígbà ìdánwò ìkẹyìn? (Ìṣí 20:8), 12/1
Ríra ilẹ̀ Gbọ̀ngàn Ìjọba lọ́wọ́ àwọn ẹlẹ́sìn mìíràn kẹ̀? 10/15
ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI
Agbára Láti Ronú, 8/15
‘Ẹ Máa Dárí Ji Ara Yín Fàlàlà,’ 9/1
“Ẹ Máa Ṣe Olùṣọ́ Àgùntàn Agbo Ọlọ́run,” 11/15
Ẹ̀mí Ìfọ̀rọ̀rora-Ẹni-Wò, 4/15
Ẹ̀yin Alàgbà—Ẹ Kọ́ Àwọn Ẹlòmíràn, 1/1
Fífi Ìfẹ́ Hàn Nínú Agbo Ìdílé, 12/15
Fún Ọwọ́ Rẹ Lókun, 12/1
Gbin Òdodo, Kí O sì Ká Inú-Rere-Onífẹ̀ẹ́ (Òwe 11), 7/15
Gbogbo Orílẹ̀-Èdè Ni Ọlọ́run Tẹ́wọ́ Gbà, 4/1
Ibi Ìfarapamọ́sí Kúrò Lọ́wọ́ Ẹ̀fúùfù, 2/15
“Ìgbàlà Jẹ́ Ti Jèhófà” (ètò ìfọkànsin orílẹ̀-èdè ẹni), 9/15
Ìgbà Wo Ni Jèhófà Máa Ń Bù Kún Ìsapá Tí A Fi Taratara Ṣe? 8/1
Ìmọ́tótó, 2/1
Ìnìkanwà, 3/15
Irú Ojú Wo Ló Yẹ Ká Máa Fi Wo Àdánwò? 9/1
Ìwà Títọ́, 8/15
Ìwà Títọ́ Ń Ṣamọ̀nà Àwọn Adúróṣánṣán, (Òwe 11) 5/15
Lílo Ìgbésí Ayé Wa Lọ́nà Tí Inú Jèhófà Dùn Sí, 11/15
“Máa Kọ́ Ara Rẹ,” 10/1
Ǹjẹ́ Bó O Ṣe Ń Kọ́ni Múná Dóko? 7/1
Oríyìn, 11/1
Owú Jíjẹ, 10/15
Ọ̀rọ̀ Àṣírí, 6/15
Pípàdé Pọ̀, 11/15
Rírìn ní Ipa Ọ̀nà Jèhófà, 7/1
Títọ́ Ọmọ Nílẹ̀ Òkèèrè, 10/15
Títọrọ Àforíjì, 11/1
‘Wíwàásù Ọ̀rọ̀ Náà’ Ń Mú Ìtura Wá, 1/15
ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ
Àǹfààní Kíkópa Nínú Ìmúgbòòrò Iṣẹ́ Náà Lẹ́yìn Ogun (F. Hoffmann), 10/1
A Ò Kúrò Nídìí Iṣẹ́ Tá A Yàn fún Wa (H. Bruder), 11/1
Ẹgbẹ́ Àwọn Ará Kárí Ayé fún Mi Lókun (T. Kangale), 7/1
Fífi Ẹ̀mí Ìfara-Ẹni-Rúbọ Sìn (D. Rendell), 3/1
Gbígbin Ìfẹ́ fún Jèhófà Sọ́kàn Àwọn Ọmọ Wa (W. Matzen), 5/1
Ibi Tá A Ti Ń Ṣiṣẹ́ Míṣọ́nnárì Di Ilé Wa (D. Waldron), 12/1
Ìfọkànsin Ọlọ́run Mú Èrè Wá fún Mi (W. Aihinoria), 6/1
Jèhófà Kọ́ Wa Ní Ìfaradà (A. Apostolidis), 2/1
Jèhófà Ti Fún Mi ní “Agbára Tí Ó Ré Kọjá Ìwọ̀n Ti Ẹ̀dá” (H. Marks), 1/1
“Mi Ò Ní Yí Ohunkóhun Padà!” (G. Allen), 9/1
Mo Gbó Mo sì Tọ́ (M. Smith), 8/1
JÈHÓFÀ
Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà, Tó Jẹ́ Ẹni Gidi, 1/15
Lẹ́tà Mẹ́rin Tó Dúró fún Orúkọ Ọlọ́run Wà Nínú Ìtumọ̀ Septuagint, 6/1
Ta Ni Ọlọ́run? 5/15
JÉSÙ KRISTI
Ìbí Jésù, 12/15
LÁJORÍ ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
A Wẹ̀ Wá Mọ́ Láti Jẹ́ Èèyàn fún Iṣẹ́ Àtàtà, 6/1
Àwọn Ìbùkún Ìhìn Rere, 1/1
Àwọn Kristẹni Ń Jọ́sìn ní Ẹ̀mí àti Òtítọ́, 7/15
Àwọn Kristẹni Tí Kì Í Dá sí Tọ̀túntòsì Láwọn Ọjọ́ Ìkẹyìn, 11/1
“Àwọn Ohun Ọlá Ńlá Ọlọ́run” Ń Ru Wá Sókè, 8/1
Àwọn Wo Ni Yóò La Ọjọ́ Jèhófà Já? 5/1
A Ti Mú Wa Gbára Dì fún Iṣẹ́ Olùkọ́ni Ní Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, 2/15
Báwo Ni Òtítọ́ Ti Ṣeyebíye Tó Lójú Rẹ? 3/1
Dídé Ojú Ìwọ̀n Ohun Tí Ọlọ́run Béèrè Ń Gbé Jèhófà Ga, 5/1
Èé Ṣe Tó Fi Yẹ Kó O Ṣe Batisí? 4/1
“Ènìyàn Mìíràn Kò Tíì Sọ̀rọ̀ Báyìí Rí,” 10/15
Ẹ Fi Ìdúróṣinṣin Tẹrí Ba fún Ọlá Àṣẹ Ọlọ́run, 8/1
Ẹ Fi Ìfọkànsìn Ọlọ́run Kún Ìfaradà Yín, 7/15
“Ẹ Kọ Ojú Ìjà sí Èṣù,” 10/15
Ẹ Máa Fi Ọkàn-Àyà Tó Fẹsẹ̀ Múlẹ̀ Ṣinṣin Sin Jèhófà, 4/1
Ẹ Máa Sìn ní Ìfẹ̀gbẹ́kẹ̀gbẹ́, 11/15
‘Ẹ Pọkàn Pọ̀ Ju Ti Àtẹ̀yìnwá Lọ,’ 9/15
“Ẹ Sún mọ́ Ọlọ́run,” 12/15
“Ẹ Tọ́jú Ìwà Yín Kí Ó Dára Lọ́pọ̀lọpọ̀ Láàárín Àwọn Orílẹ̀-Èdè,” 11/1
Fífarada ‘Ẹ̀gún Nínú Ẹran Ara’ 2/15
Gbádùn Ìdákẹ́kọ̀ọ́ Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, 12/1
Gbogbo Kristẹni Tòótọ́ Ni Ajíhìnrere, 1/1
Ìdákẹ́kọ̀ọ́ Tó Ń Mú Ká Di Olùkọ́ Tó Pegedé, 12/1
Ìmọ́lẹ̀ Ọlọ́run Ń Lé Òkùnkùn Dà Nù! 3/1
Ire Wa Ni Òfin Ọlọ́run Wà Fún, 4/15
Jèhófà Bìkítà fún Yín, 10/15
Jèhófà Fi Ìmọ́lẹ̀ Bu Ẹwà Kún Àwọn Èèyàn Rẹ̀, 7/1
Jèhófà Jẹ́ Aláìlẹ́gbẹ́ Nínú Rere Ṣíṣe, 1/15
Jèhófà Kórìíra Ìwà Àdàkàdekè, 5/1
Jèhófà Ń Bù Kún Àwọn Onígbọràn, Ó sì Ń Dáàbò Bò Wọ́n, 10/1
Jẹ́ Onígbọràn Bí Òpin Ti Ń Sún Mọ́lé, 10/1
Jíjàǹfààní Inú-Rere-Onífẹ̀ẹ́ Jèhófà, 5/15
“Kì Í Bá Wọn Sọ̀rọ̀ Láìsí Àpèjúwe,” 9/1
Kòṣeémáàní Làwa Kristẹni Jẹ́ fún Ara Wa, 11/15
Kristi Ni Aṣáájú Ìjọ Rẹ̀, 3/15
Máa Fara Wé Olùkọ́ Ńlá Náà, 9/1
Máa Fi Àwọn Ìlànà Ọlọ́run Tọ́ Ìṣísẹ̀ Ara Rẹ, 4/15
Máa Fi Inú-Rere-Onífẹ̀ẹ́ Hàn Sáwọn Aláìní, 5/15
Máa Fi Ìwà Rere Kristẹni Kọ́ Ara Rẹ Àtàwọn Ẹlòmíràn, 6/15
Máa Fi Ohun Tó O Ti Kọ́ Sílò, 9/15
Máa Ṣe Bí Ọba, 6/15
Máa Ṣe Rere Nìṣó, 1/15
“Máa Tọ̀ Mí Lẹ́yìn Nígbà Gbogbo,” 8/15
“Mo Fi Àwòṣe Lélẹ̀ fún Yín,” 8/15
Ní Inú Dídùn sí Òdodo Jèhófà, 6/1
Ǹjẹ́ O Ti Rí “Ẹ̀mí Òtítọ́” Náà Gbà? 2/1
Ǹjẹ́ O Wà Lára Àwọn Tí Ọlọ́run Nífẹ̀ẹ́? 2/1
Ògo Jèhófà Tàn Sára Àwọn Èèyàn Rẹ̀, 7/1
Ṣé Lóòótọ́ Lo Gbà Pé Kristi Ni Aṣáájú Wa? 3/15
Wọ́n Fara Da Ẹ̀gún Nínú Ẹran Ara Wọn, 2/15
Wọ́n Ń Bá A Lọ ní Rírìn Nínú Òtítọ́, 7/15
“Yóò sì Sún mọ́ Yín,” 12/15
Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN
Aṣáájú Rere, 3/15
Àwọn Aládùúgbò, 9/1
“Àwọn Amòye Mẹ́ta,” 12/15
Àwọn Ère Ìjọsìn, 7/1
Àwọn Èrò Èké Nípa Ikú, 6/1
“Àwọn Ẹni Mímọ́,” 9/15
Àwọn Ìlànà Ọlọ́run Lè Ṣe Ọ́ Láǹfààní, 2/15
Àwọn Ọmọ Ìyá Kan Náà Tí Ìwà Wọ́n Yàtọ̀ Síra (Kéènì àti Ébẹ́lì), 1/15
Àwọn Ọmọlẹ́yìn Waldo, 3/15
Ayé Ìgbàanì Ṣègbé (Ìkún Omi), 3/1
Ẹ̀bi Ta Ni—Ṣé Ẹ̀bi Rẹ Ni àbí Ti Apilẹ̀ Àbùdá Rẹ? 6/1
Ẹ̀kọ́ Àríkọ́gbọ́n Lára Ẹyẹ Àkọ̀, 8/1
Ẹ̀kọ́ Àríkọ́gbọ́n Látinú Ìtàn Róòmù (àwọn eré ìdárayá oníjà àjàkú akátá), 6/15
Gbẹ́kẹ̀ Lé Ọlọ́run Tó Jẹ́ Ẹni Gidi 1/15
Ìbatisí Clovis, 3/1
Ibo Lo Ti Lè Rí Ìfọ̀kànbalẹ̀? 4/15
Igi Tó “Ń Sunkún” àti “Omijé” Rẹ̀ Tó Wúlò Púpọ̀, 1/15
Ìgbàgbọ́ àti Ọgbọ́n Orí, Ǹjẹ́ Wọ́n Bára Tan? 4/1
Ìgbàgbọ́ Nínú Ohun Asán, 8/1
Ikú, 6/1
Ìlú Tó Wà Lórí Òkè, 2/1
Iná Ọ̀run Àpáàdì, 7/15
Ìṣòro Aráyé, 6/15
Ìṣòro Jíjẹ́ Aláàbọ̀ Ara Kò Ní Sí Mọ́, 5/1
Ìtùnú Nínú Ayé Oníwàhálà, 10/1
Jóṣúà, 12/1
Kíkun Òkú Lọ́ṣẹ, 3/15
Má Ṣe Jẹ́ Kí A Tàn Ọ́ Jẹ, 7/1
Nikodémù, 2/1
Ǹjẹ́ A Nílò Àwọn Ibi Ìjọsìn? 11/15
Ǹjẹ́ Ìwà Kẹ́lẹ́gbẹ́mẹgbẹ́ Lè Tán Láé? 1/1
Ǹjẹ́ Ó Yẹ Kó O Jẹ́ Ẹni Tó Tutù Lẹ́dàá? 10/1
“Obìnrin Títayọ Lọ́lá” (Rúùtù), 6/15
Ohun Kan Tó Níye Lórí Ju Àwọn Ìṣúra Íjíbítì Lọ (Mósè), 6/15
Ọ̀nà Wo Ló Yẹ Kí Ìsìn Máa Gbà Rí Owó Tó Ń Ná?
Pẹpẹ Kan fún Ọlọ́run Tí Kò Lórúkọ, 7/15
Sátánì—Ṣé Olubi Tó Wà Lóòótọ́ Ni àbí Ẹni Ìtàn Àròsọ Lásán? 10/15
Ṣáfánì àti Ìdílé Rẹ̀, 12/15
Ṣọ́ọ̀ṣì àti Ìjọba ní Ilẹ̀ Ọba Byzantium, 2/15
Tá Ló Yẹ Kó O Jẹ́ Adúróṣinṣin Sí? 8/15
Tertullian, 5/15
“Wò Ó, Ó Lè Dùn Ẹ́ O,” 3/1
Yoga, 8/1