Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Ṣé Wàá Fẹ́ Ká Bẹ̀ Ọ́ Wò?

Ṣé Wàá Fẹ́ Ká Bẹ̀ Ọ́ Wò?

Ṣé Wàá Fẹ́ Ká Bẹ̀ Ọ́ Wò?

Àní nínú ayé onídààmú yìí, ìmọ̀ pípéye láti inú Bíbélì nípa Ọlọ́run, Ìjọba rẹ̀, àti ète àgbàyanu rẹ̀ fún aráyé, lè fún ọ láyọ̀. Bí o bá fẹ́ ìsọfúnni síwájú sí i tàbí kí ẹnì kan kàn sí ọ nílé láti darí ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì pẹ̀lú rẹ̀ lọ́fẹ̀ẹ́, jọ̀wọ́ kọ̀wé sí Jehovah’s Witnesses, P.M.B. 1090, Benin City 300001, Edo State, Nigeria, tàbí sí àdírẹ́sì tí ó bá yẹ lára èyí tí a tò sí ojú ìwé 2.