Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ Ọdún 2005

Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ Ọdún 2005

Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ Ọdún 2005

Ó ń tọ́ka sí Ilé Ìṣọ́ tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde

ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ

Agbára Tí Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run Ní, 2/15

Àpéjọ Àyíká ní Àgọ́ Àwọn Tí Ogun Lé Kúrò Nílé (Kẹ́ńyà), 4/15

Àrọko Ọsirélíà, 4/1

Àwọn Èwe Ń Yin Jèhófà ní Iléèwé, 6/15

Àwọn Ẹlẹ́rìí Mẹ́síkò Ń Ran Àwọn Ará Ṣáínà Lọ́wọ́, 12/15

Àwọn Ẹlẹ́sìn Menno Fẹ́ Mọ Ohun Tí Bíbélì Kọ́ni (Bolivia), 9/1

Àwọn Olóòótọ́ Èèyàn, 6/1

Ẹ̀rí Tó Fi Ìfẹ́, Ìgbàgbọ́ àti Ìgbọràn Hàn (Ibi Ìtẹ̀wé ní Oko Watchtower), 12/1

Ibi Tí Ẹ̀sìn Kristẹni Ti Gbilẹ̀ Nígbà Ìjímìjí (Ítálì), 6/15

‘Ìfẹ́ Yín Lápapọ̀ Ń Pọ̀ Sí I’ (Japan), 11/15

“Ìgbàgbọ́ Wọn Ò Yẹ̀ Lábẹ́ Àdánwò” (fídíò), 3/1

“Ìhìn Rere Fáwọn Èèyàn Gbogbo Orílẹ̀-Èdè” (ìwé kékeré, Gẹ̀ẹ́sì), 12/1

Ìkẹ́kọ̀ọ́yege ní Ilé Ẹ̀kọ́ Gílíádì, 7/1

“Ilẹ̀ Ẹyẹ Idì” (Alibéníà), 10/15

Ìròyìn Iṣẹ́ Ìwàásù Wa ní Áfíríkà, 3/1

Ìwà Rere Méso Jáde (Japan), 11/1

Makedóníà, 4/15

“Ọ̀kan Lára Ọjọ́ Tínú Mi Dùn Jù Lọ Láyé Mi” (Ọsirélíà), 11/1

Ọrẹ, 11/1

Saba, 2/15

‘Wàásù Ìtúsílẹ̀ fún Àwọn Òǹdè’ (iṣẹ́ ìwàásù lọ́gbà ẹ̀wọ̀n), 12/15

‘Wọn Ì Bá Ti Dá Wọn Sílẹ̀,’ 8/15

“Wọn Kò Ṣe Ohun Tó Lòdì sí Ìgbàgbọ́ Wọn,” 7/15

Wọ́n Ń Sọ Ìhìn Rere Fáwọn Adití (Sípéènì), 11/1

‘Wọ́n Ṣe Inúnibíni sí Riet Nítorí Ìgbàgbọ́ Rẹ̀’ (N. Riet), 6/15

BÍBÉLÌ

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Àwọn Onídàájọ́, 1/15

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Rúùtù, 3/1

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Sámúẹ́lì Kìíní, 3/15

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Sámúẹ́lì Kejì, 5/15

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Àwọn Ọba Kìíní, 7/1

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Àwọn Ọba Kejì, 8/1

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Kíróníkà Kìíní, 10/1

Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Kíróníkà Kejì, 12/1

Bíbélì Berleburg, 2/15

Bíbélì Èdè Ítálì—Ohun Tí Ojú Àwọn Olùtumọ̀ Rí, 12/15

Bíbélì Èdè Jámánì Ìjímìjí Lo Orúkọ Ọlọ́run, 9/1

Bíbélì Lè Ràn Ọ́ Lọ́wọ́ Láti Rí Ayọ̀, 8/1

Bíbélì Ọba, 8/15

Ẹ̀kọ́ Òtítọ́, 7/15

Ibi Ìkówèésí Àkọ́kọ́ Nílẹ̀ Rọ́ṣíà, 7/15

Ìtàn Inú Bíbélì—Ṣé Òótọ́ Ni àbí Àròsọ? 4/15

Ohun Tó Lè Mú Ìtumọ̀ Èdè Rọrùn, 4/15

Òkun Gálílì (ọkọ̀ ojú omi ayé àtijọ́), 8/15

Òkúta “Píìmù” Fi Hàn Pé Òótọ́ Ni Ìtàn inú Bíbélì, 3/15

“Ó Parí O” (Ìwé Mímọ́ Kristian Lédè Griki ní Ìtumọ̀ Ayé Titun lédè Lingala), 7/1

Ṣé Ìmọ̀ Sáyẹ́ǹsì àti Bíbélì Ta Ko Ara Wọn? 4/1

ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ

“Áńgẹ́lì” Pétérù (Iṣe 12:15), 6/1

“A ó pa [àwọn obìnrin] mọ́ láìséwu nípasẹ̀ ọmọ bíbí” (1Ti 2:15), 5/1

Báwo ni Sámúsìnì ṣe lè fọwọ́ kan òkú kó ṣì tún jẹ́ Násírì? 1/15

“Bóyá” (Sef 2:3), 8/1

Dáfídì àtàwọn tó wà pẹ̀lú rẹ̀ jẹ búrẹ́dì àfihàn, 3/15

Eré kọ̀ǹpútà oníwà ipá, 9/15

Iṣẹ́ tó gba pé kó máa gbé ìbọn, 11/1

Kí nìdí tí Ọlọ́run ò fi pa Dáfídì àti Bátí-ṣébà? 5/15

Ǹjẹ́ ìtakora wà lórí ọ̀rọ̀ jíjẹ òkú ẹran? (Le 11:40; Diu 14:21), 7/1

Ǹjẹ́ Kristẹni lè fún òṣìṣẹ́ ìjọba lówó kó lè ṣe iṣẹ́ tó yẹ kó ṣe? 4/1

Ǹjẹ́ Sámúsìnì ya kìnnìún sí méjì bíi pé ọmọ ẹran ni? 1/15

Ǹjẹ́ Sólómọ́nì yóò jíǹde? 7/15

Ohun tí ìmọ́lẹ̀ Ṣèkínà dúró fún, 8/15

Pọ́ọ̀lù sọ pé: “Farisí ni mí” (Iṣe 23:6), 4/15

Ṣé Jésù ni “ẹnì kan ṣoṣo tí ó ní àìkú” àti “ẹni tí kò sí ọ̀kan nínú àwọn ènìyàn tí ó ti rí i” ń tọ́ka sí? (1Ti 6:15, 16), 9/1

Ṣé Jésù ni Sítéfánù gbàdúrà sí? 1/1

Ṣé òótọ́ ni Dáfídì dá àwọn òǹdè lóró? 2/15

ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI

‘Afọgbọ́nhùwà Ń Ronú Nípa Ìṣísẹ̀ Ara Rẹ̀’ (Owe 14), 7/15

Àkókò Oúnjẹ, 1/1

A Lè Borí Àdánwò Èyíkéyìí! 6/15

Àwọn Àṣà Ìbílẹ̀ Tí Inú Ọlọ́run Kò Dùn Sí, 1/1

Bí A Ṣe Lè Fi Jèhófà Ṣe Ọlọ́run Wa, 4/1

Èdèkòyédè Láàárín Tọkọtaya, 6/1

Èrò Táwọn Èèyàn Ní Nípa Wa, 9/15

“Ẹ Ní Ẹ̀mí Aájò Àlejò,” 1/15

Fífarabalẹ̀ Tẹ́tí Síni, 11/15

Fi Ọgbọ́n Ọlọ́run Yọ Àwọn Ọmọ Nínú Ewu, 1/1

‘Ìbẹ̀rù Jèhófà Ni Ọgbọ́n’ (Owe 14), 9/15

Ìgbà Wo Ló Yẹ Kéèyàn Bínú? 8/1

Ìgboyà Nígbà Àtakò, 5/1

Ìṣòtítọ́, 9/1

Làákàyè, 5/15

Máa Lo Ọjọ́ Kọ̀ọ̀kan Lọ́nà Rere, 5/1

Má Ṣe Fàyè Gba Èrò Òdì! 9/15

Má Ṣe Juwọ́ Sílẹ̀ Nínú Ṣíṣe Ohun Tó Dára, 6/1

Ǹjẹ́ Ìwọ àti Ìdílé Rẹ Máa Ń Jùmọ̀ Sọ̀rọ̀?, 6/1

Ǹjẹ́ O Kọ́ Ẹ̀rí Ọkàn Rẹ Dáadáa? 10/1

Ǹjẹ́ Ò Ń Fi Iṣẹ́ Ti Ìgbàgbọ́ Rẹ Lẹ́yìn? 4/15

Ǹjẹ́ O ‘Ní Ọrọ̀ Sọ́dọ̀ Ọlọ́run’? 10/1

Ǹjẹ́ Òtítọ́ Ń So Èso Nínú Àwọn Tó Ò Ń Kọ́? 2/1

Ǹjẹ́ Ó Yẹ Kó O Máa Fi Ara Ẹ Wé Àwọn Ẹlòmíì? 2/15

Orí Ìpìlẹ̀ Wo Lò Ń Kọ́ Ìgbésí Ayé Rẹ Lé? 5/15

Yíyanjú Aáwọ̀, 3/1

ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ

A Fi Gbogbo Ọkàn Wa Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà (N. Holtorf), 1/1

Àpẹẹrẹ Àwọn Òbí Mi fún Mi Lókun (J. Rekelj), 10/1

Bí Mo Tilẹ̀ Jẹ́ Aláìlera, Mo Di Alágbára (L. Engleitner), 5/1

Inú Mi Dùn Pé Mo Kópa Nínú Iṣẹ́ Ìkọ́nilẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì (A. Matheakis), 7/1

Ipò Wa Tó Ń Yí Padà Jẹ́ Ká Lè Wàásù Láwọn Ibi Jíjìnnà Réré (R. Malicsi), 3/1

Jèhófà Máa Ń San Èrè Rẹpẹtẹ (R. Stawski), 8/1

Mo Gbádùn ‘Ìgbésí Ayé Ìsinsìnyí’ Dé Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́! (T. Buckingham), 6/1

Mo Ní Ìfaradà Bí Ọmọ Ogun Kristi (Y. Kaptola), 9/1

Mo Pinnu Láti Máa Sin Ẹlẹ́dàá Nìṣó (C. Benanti), 12/1

Obìnrin Tó Ṣẹ́gun Lọ́nà Àrà Ọ̀tọ̀ (E. Ludolph), 5/1

Ọlọ́run Fún Mi Ní ‘Ohun Tí Ọkàn Mi Ń Fẹ́’ (D. Morgou), 11/1

Ọmọ Òrukàn Rí Baba Onífẹ̀ẹ́ (D. Sidiropoulos), 4/1

JÈHÓFÀ

Jèhófà Kì Yóò Fi Ọ́ Sílẹ̀ Lọ́nàkọnà, 10/15

Jèhófà Máa Ń Ṣe Ohun Tó Tọ́ Nígbà Gbogbo, 2/1

Jẹ́ Kí “Àsọjáde” Jèhófà Máa Ṣọ́ Ọ, 9/1

JÉSÙ KRISTI

Ipa Wo Ni Jésù Kristi Ń Ní Lórí Rẹ? 3/15

Ta Ni Jésù Kristi? 9/15

KÀLẸ́ŃDÀ

Àwọn Ọ̀dọ́ Ń Fìyìn fún Jèhófà, 3/15

Ẹ̀mí Ìfara-Ẹni-Rúbọ, 11/15

Ìdílé Wà Níṣọ̀kan, 5/15

Ogunlọ́gọ̀ Èèyàn Ń Di Olùjọsìn Jèhófà, 9/15

Ọjọ́ Ogbó Jẹ́ “Adé Ẹwà,” 1/15

Wọn Ò Lọ́kọ Wọn Ò Láya àmọ́ Ọkàn Wọn Balẹ̀, 7/15

LÁJORÍ ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

Àkókò Yìí Gan-An Ló Yẹ Kó O Gbé Ìgbésẹ̀ Kánkán, 12/15

A Ó Máa Rìn Ní Orúkọ Jèhófà Ọlọ́run Wa, 9/1

Àsọtẹ́lẹ̀ Hóséà Ń Fún Wa Níṣìírí Láti Bá Ọlọ́run Rìn, 11/15

“A Ti Rà Yín ní Iye Kan,” 3/15

Àwa Kristẹni Ń Gbé Ògo Jèhófà Yọ, 8/15

Àwọn Èèyàn “Láti Inú Gbogbo Èdè” Ń Gbọ́ Ìhìn Rere, 12/1

Àwọn Èèyàn Ń Wá ‘Péálì Olówó Iyebíye’ Lónìí, 2/1

Àwọn Ọ̀nà Jèhófà Dúró Ṣánṣán, 11/15

‘Àwọn Tí Ń Mú Ìhìn Rere Ohun Tí Ó Dára Jù Wá,’ 7/1

Àwọn Wo Ni Yóò Jíǹde? 5/1

Bá A Ṣe Lè Di Òjíṣẹ́ Tó Mọṣẹ́ Rẹ̀ Níṣẹ́ Tó Tún Mọwọ́ Yí Padà, 12/1

Bá Ọlọ́run Rìn Kó O Lè Kórè Ohun Tó Dára, 11/15

Báwo Ni Ìgbàgbọ́ Nínú Àjíǹde Ṣe Jinlẹ̀ Tó Lọ́kàn Rẹ? 5/1

Bí A Ò Ṣe Ní Wà Láàyè fún Ara Wa Mọ́, 3/15

Bí Tọkọtaya Ṣe Lè Láyọ̀ Lóde Òní, 3/1

Ẹ Bá Ọlọ́run Rìn Lákòókò Hílàhílo Yìí, 9/1

Ẹ Jẹ́ Kí Inú Yín Máa Dùn Pé Kristẹni Ni Yín! 2/15

Ẹ̀kọ́ Àjíǹde Kàn Ọ́, 5/1

‘Ẹ Máa Ṣọ́nà’—Wákàtí Ìdájọ́ Ti Dé! 10/1

Ẹ Máa Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Tí Jésù Fi Lélẹ̀, 1/1

“Ẹ Máa Wádìí Ohun Tí Ẹ̀yin Fúnra Yín Jẹ́,” 7/15

Ẹ̀yin Èwe, Ẹ Yin Jèhófà! 6/15

Ẹ̀yin Òbí—Báwo Lẹ Ṣe Fẹ́ Kí Ọjọ́ Ọ̀la Àwọn Ọmọ Yín Rí? 10/1

Ẹ̀yin Òbí, Ẹ Dáàbò Bo Ogún Iyebíye Tẹ́ Ẹ Ní, 4/1

Ẹ̀yin Òbí, Ẹ Pèsè Ohun Tí Ìdílé Yín Nílò, 6/15

Gbẹ́kẹ̀ Lé Ọ̀rọ̀ Jèhófà, 4/15

Ìhìn Rere fún Àwọn Èèyàn Gbogbo Orílẹ̀-Èdè, 7/1

Ìmọ̀ràn Ọlọgbọ́n fún Àwọn Tọkọtaya, 3/1

Inú Rere Àìlẹ́tọ̀ọ́sí La Fi Gbà Wọ́n Là, Kì Í Ṣe Iṣẹ́ Nìkan, 6/1

Ìran Tó Jẹ́ Àsọtẹ́lẹ̀ Nípa Ìjọba Ọlọ́run Nímùúṣẹ, 1/15

Ìtọ́ni Jésù Ń Ràn Wá Lọ́wọ́ Láti Jẹ́rìí Kúnnákúnná, 1/1

Jèhófà Mọ Iye ‘Irun Orí Rẹ,’ 8/1

Jèhófà Ń Dáàbò Bo Àwọn Tó Ní Ìrètí Nínú Rẹ̀, 6/1

Jèhófà Ni “Olùsẹ̀san fún Àwọn Tí Ń Fi Taratara Wá A,” 8/1

Jèhófà Ni Olùṣọ́ Àgùntàn Wa, 11/1

Jẹ́ Kí Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run Máa Tànmọ́lẹ̀ sí Òpópónà Rẹ, 4/15

Kristi Làwọn Àsọtẹ́lẹ̀ Tọ́ka Sí, 1/15

Máa Bá A Lọ Ní Títẹ̀lé Ìṣísẹ̀ Jésù Kristi, 9/15

‘Máa Kó Ara Rẹ Níjàánu Lábẹ́ Ibi,’ 5/15

Máa Rìn Nípa Ìgbàgbọ́, Má Ṣe Rìn Nípa Ohun Tó O Lè Fojú Rí! 9/15

Má Ṣe Ní Ẹ̀mí Ìgbéraga, 10/15

Má Ṣe Sọ Ìwà Kristẹni Nù, 2/15

Mọ Àwọn Ọ̀nà Jèhófà, 5/15

Ní Ojúlówó Ẹ̀mí Ìrẹ̀lẹ̀, 10/15

Ǹjẹ́ O Máa Ń Ṣòótọ́ Nínú Gbogbo Nǹkan? 7/15

Ǹjẹ́ Wàá Gbé Ògo Ọlọ́run Yọ? 8/15

Òfin Ìfẹ́ Tá A Kọ Sínú Ọkàn, 8/15

Ogun Iyebíye Làwọn Ọmọ Wa, 4/1

Ṣé Wàá Bá Ọlọ́run Rìn? 11/1

Ta Ni Ìwọ Ń Ṣègbọràn Sí—Ọlọ́run Ni Tàbí Ènìyàn? 12/15

‘Wọ́n Rí Péálì Olówó Iyebíye,’ 2/1

Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN

Àjíǹde, 5/1

Amágẹ́dọ́nì, 12/1

Àmì Tó Fi Hàn Pé Jésù Ti Wà Níhìn-ín, 10/1

Àsìkò Ọdún, 12/15

Àwọn Èèyàn Ń Wá Ìbàlẹ̀ Ọkàn, 7/1

“Awọn Ti Nsọkalẹ Lọ si Okun Ninu Ọkọ̀,” 10/15

‘Bí Ẹnì Kan Bá Fipá Gbéṣẹ́ fún Ọ’ (Mt 5:41), 2/15

Ẹ̀kọ́ Kíkọ́—Nísinsìnyí àti Títí Láé, 4/15

Ẹ̀kọ́ Òtítọ́, 7/15

Ẹ̀kọ́ Tó Dára Jù Lọ, 10/15

Ẹ̀mí Rẹ Ṣe Pàtàkì, 2/1

Ẹ̀sìn Kristẹni Láàárín Àwọn Júù Ọ̀rúndún Kìíní, 10/15

“Idà Jèhófà àti Ti Gídíónì!” 7/15

Ìgbà Ọdún Kérésì, 12/15

Ikú, 8/15

Ipò Òṣì, 5/15

Ìràpadà Túbọ̀ Fi Òdodo Ọlọ́run Hàn, 11/1

Iṣẹ́ Àrà inú Ìṣẹ̀dá Ń Gbé Jèhófà Ga, 11/15

Iṣẹ́ Ìwàásù Mú Kí Wọ́n Ṣe Inúnibíni sí Sọ́ọ̀lù, 1/15

Iṣẹ́ Ìyanu, 2/15

Iṣẹ́ Ṣíṣe—Ìbùkún Ni Tàbí Ègún? 6/15

Ìṣọ̀kan Ayé, 6/1

Mari—Ìlú Pàtàkì Kan Tó Wà Nínú Aṣálẹ̀, 5/15

Ǹjẹ́ Èṣù Wà Lóòótọ́? 11/15

Ǹjẹ́ Ẹnì Kan Lè Yí Ayé Padà? 11/1

Ǹjẹ́ Ìsìn Lè Mú Kí Aráyé Wà Níṣọ̀kan? 1/1

Ǹjẹ́ O Lè Pinnu Ọjọ́ Ọ̀la Rẹ? 1/15

‘Òkúta Aláwọ̀ Pupa Tí Ó Ṣeyebíye’ (Iṣi 4:3), 3/15

Philo Ará Alẹkisáńdíríà, 6/15

Pọ́ńtíù Pílátù, 9/15

Sámúsìnì Borí, 3/15