Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

September 15, 2008

Ẹ̀dà Tó Wà Fún Ìkẹ́kọ̀ọ́

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ TÁ A MÁA KẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ Ọ̀SẸ̀:

November 3-9

Jèhófà Jẹ́ “Olùpèsè Àsálà” Láyé Ìgbà Tí Wọ́n Ń Kọ Bíbélì

OJÚ ÌWÉ 3

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 74, 44

November 10-16

Jèhófà Jẹ́ “Olùpèsè Àsálà” fún Wa

OJÚ ÌWÉ 7

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 153, 3

November 17-23

Máa Jẹ́ Kí Ìgbéyàwó Rẹ Jẹ́ “Okùn Onífọ́nrán Mẹ́ta”

OJÚ ÌWÉ 16

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 117, 173

November 24-30

Má Ṣe Fàyè Gba “Ẹ̀mí Ayé”

OJÚ ÌWÉ 20

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 10, 191

Ohun Táwọn Àpilẹ̀kọ Tá a Máa Kẹ́kọ̀ọ́ Dá Lé

Àpilẹ̀kọ fún Ìkẹ́kọ̀ọ́ 1 àti 2 OJÚ ÌWÉ 3 sí 11

Àpilẹ̀kọ méjèèjì yìí dá lórí Sáàmù àádọ́rin, èyí tó sọ pé Jèhófà jẹ́ “Olùpèsè àsálà.” Àwọn àpilẹ̀kọ náà ṣàgbéyẹ̀wò bí Jèhófà ṣe pèsè àsálà fáwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ láyé ìgbà tí wọ́n ń kọ Bíbélì àti bó ṣe ń pèsè àsálà fún wa lóde òní.

Àpilẹ̀kọ fún Ìkẹ́kọ̀ọ́ 3 OJÚ ÌWÉ 16 sí 20

Ó lè ṣòro fáwọn lọ́kọláya láti máa wà níṣọ̀kan lóde òní, kódà káwọn méjèèjì jẹ́ ìránṣẹ́ Jèhófà. Àwọn àbá nípa báwọn tọkọtaya ṣe lè jẹ́ kí Jèhófà wà nínú ìgbéyàwó wọn wà nínú àpilẹ̀kọ yìí, ó sì tún sọ àwọn ohun tí wọ́n lè ṣe nígbà tí ìṣòro bá ń yọjú.

Àpilẹ̀kọ fún Ìkẹ́kọ̀ọ́ 4 OJÚ ÌWÉ 20 sí 24

A ní láti yan èyí tá a fẹ́ níbẹ̀: Ṣé a máa fẹ́ gba ẹ̀mí mímọ́ Ọlọ́run ká sì jẹ́ kó máa darí wa, àbí ẹ̀mí ayé la óò jẹ́ kó máa darí wa? Àpilẹ̀kọ yìí sọ bá a ṣe lè rí ẹ̀mí Ọlọ́run gbà àti bá a ṣe lè dènà ẹ̀mí ayé, ó sì tún ṣàlàyé èyí tá a lè yàn nínú méjèèjì tó máa mú ká láyọ̀.

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ:

Máa Kún fún Ìmọ̀ Pípéye Nípa Kíkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Tọkàntọkàn

OJÚ ÌWÉ 12

Wíwàásù ní Ọjà

OJÚ ÌWÉ 25

Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Jésù—Sin Ọlọ́run bí Ọlọ́run Ṣe Fẹ́

OJÚ ÌWÉ 26

Ọ̀rọ̀ Jèhófà Yè—Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Tẹsalóníkà Kìíní àti Ìkejì, àti Ìwé Tímótì Kìíní àti Ìkejì

OJÚ ÌWÉ 29

Ìbéèrè Láti Ọwọ́ Àwọn Òǹkàwé

OJÚ ÌWÉ 32