Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ 2009
Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ 2009
Ó ń tọ́ka sí Ilé Ìṣọ́ tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde
ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
Àwọn Áńgẹ́lì Jẹ́ “Ẹ̀mí fún Iṣẹ́ Ìsìn Gbogbo Ènìyàn,” 5/15
Àwọn Ìṣẹ̀dá Jèhófà Ń Fi Ọgbọ́n Rẹ̀ Hàn, 4/15
Àwọn Olódodo Yóò Máa Yin Ọlọ́run Títí Láé, 3/15
Bá A Ṣe Lè Máa Hùwà Tó Bójú Mu Gẹ́gẹ́ Bí Òjíṣẹ́ Ọlọ́run, 11/15
Bá A Ṣe Lè Máa Ṣe Ọ̀rẹ́ Nínú Ayé Aláìnífẹ̀ẹ́ Yìí, 10/15
Bá A Ṣe Lè Mọyì Jésù Tó Jẹ́ Dáfídì àti Sólómọ́nì Títóbi Jù, 4/15
Bá A Ṣe Lè Mọyì Jésù Tó Jẹ́ Mósè Títóbi Jù, 4/15
Bá A Ṣe Lè Rí Ìṣúra Tá A Rọra Fi Pa Mọ́ Sínú Kristi, 7/15
Bí Ọ̀rọ̀ Jésù Ṣe Lè Sọni Di Aláyọ̀, 2/15
‘Ẹ Dúró Nínú Ìfẹ́ Ọlọ́run,’ 8/15
“Ẹ Jẹ́ Ẹlẹ́mìí Àlàáfíà Pẹ̀lú Gbogbo Ènìyàn,” 10/15
Ẹ Jẹ́ Kí Gbogbo Wa Jọ Yin Jèhófà, 3/15
‘Ẹ Jẹ́ Kí Iná Ẹ̀mí Máa Jó Nínú Yín,’ 10/15
Ẹ Ní Ìfẹ́ Tí Kì Í Kùnà Láé, 12/15
‘Ẹ Wà Lójúfò,’ 3/15
Ẹ̀yin Ìdílé Kristẹni Ẹ Máa Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Jésù! 7/15
Ẹ̀yin Ọ̀dọ́, Ẹ Jẹ́ Kí Ìtẹ̀síwájú Yín Fara Hàn Kedere, 5/15
Ìfẹ́ Kristi Ń Mú Ká Ní Ìfẹ́, 9/15
Ìránṣẹ́ Jèhófà Tí Wọ́n ‘Gún Nítorí Ìrélànàkọjá Wa,’ 1/15
Ìrètí Ìyè Àìnípẹ̀kun Lorí Ilẹ̀ Ayé Pa Dà Wá Sojú Tayé, 8/15
Ìwà Títọ́ Rẹ Ń Mú Ọkàn Jèhófà Yọ̀, 4/15
Jẹ́ Kí Ìfẹ́ Tó O Ní Fáwọn Ará Máa Pọ̀ Sí I, 11/15
Jẹ́ Kí Ìlọsíwájú Rẹ Máa Fara Hàn Kedere, 12/15
Jẹ́ Onígbọràn àti Onígboyà Bíi Kristi, 9/15
Jẹ́ Onítara fún Ilé Jèhófà! 6/15
Jẹ́ “Onítara fún Iṣẹ́ Àtàtà”! 6/15
Jóòbù Gbé Orúkọ Jèhófà Ga, 4/15
Kí Ni Àdúrà Rẹ Ń Sọ Nípa Rẹ? 11/15
Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Ká Má Tẹ̀ Lé “Kristi”? 5/15
Má Ṣe Jẹ́ Kí Ìṣòro Ba Ayọ̀ Rẹ Jẹ́, 12/15
Máa Bá Aládùúgbò Rẹ Sọ Òtítọ́, 6/15
Máa Kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Láti Mú Kí Àdúrà Rẹ Sunwọ̀n Sí I, 11/15
Máa Rí Ìdùnnú Nínú Iṣẹ́ Sísọni Dọmọ Ẹ̀yìn, 1/15
Máa Tẹ̀ Lé Ọ̀rọ̀ Jésù Nínú Ìwà Àti Ìṣe Rẹ, 2/15
Máa Tẹ̀ Síwájú sí Ìdàgbàdénú Torí pé “Ọjọ́ Ńlá Jèhófà Sún Mọ́lé,” 5/15
“Máa Tọ̀ Mí Lẹ́yìn,” 1/15
Mèsáyà! Ọ̀nà Ìgbàlà Tí Ọlọ́run Pèsè, 12/15
Mọyì Ojúṣe Rẹ Nínú Ìjọ, 11/15
Ǹjẹ́ ‘Ìríjú Inú Rere Àìlẹ́tọ̀ọ́sí Ọlọ́run’ Ni Ọ́? 1/15
Ǹjẹ́ O Máa Ń Tẹ̀ Lé Ọ̀rọ̀ Jésù Tó O Bá Ń Gbàdúrà? 2/15
Ǹjẹ́ O Mọyì Ohun Tí Jèhófà Ṣe Láti Dá Ọ Nídè? 9/15
Ohun Tó Mú Kí Ẹ̀kọ́ Tí Ọlọ́run Ń Kọ́ Wa Ta Yọ, 9/15
Olùṣòtítọ́ Ìríjú Náà àti Ìgbìmọ̀ Olùdarí Rẹ̀, 6/15
Ọlọ́run Ló Fún Aráyé Ní Ìrètí Ìyè Àìnípẹ̀kun Lorí Ilẹ̀ Ayé, 8/15
“Ọ̀rẹ́ Mi Ni Yín,” 10/15
Ṣé Ìrètí Ìyè Àìnípẹ̀kun Lorí Ilẹ̀ Ayé Jẹ́ Ìrètí Tó Wà Fáwọn Kristẹni? 8/15
Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Jésù Máa Fìgboyà Wàásù, 7/15
Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Jésù Máa Kọ́ni Pẹ̀lú Ìfẹ́, 7/15
Tẹjú Mọ́ Èrè Náà, 3/15
Wò ó! Ìránṣẹ́ Tí Jèhófà Tẹ́wọ́ Gbà, 1/15
Wọ́n “Ń Tọ Ọ̀dọ́ Àgùntàn Náà Lẹ́yìn Ṣáá,” 2/15
ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ
A Fi Tọ̀yàyàtọ̀yàyà Pè Ọ́ (àwọn ìpàdé), 2/1
Adágún Títóbi Jù Lọ ní Amẹ́ríkà Àárín, 9/1
Àkànṣe Àsọyé fún Gbogbo Ènìyàn, 4/1
Àwárí, (Ireland), 3/1
Ayẹyẹ Ìkẹ́kọ̀ọ́yege Ilé Ẹ̀kọ́ Gílíádì, 2/15, 9/1
Bẹ́tẹ́lì Tó Wà Ní Brooklyn Pé Ọgọ́rùn-ún Ọdún, 5/1
Ìdí Tí Wọn Kì í Fí Í Lo Ère, 2/1
Ìhìn Rere ní Ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta Èdè, 11/1
Ìjì Òjò Lórílẹ̀-Èdè Myanmar, 3/1
Ilé Ìtẹ̀wé Tó Pabanbarì (Oko Watchtower lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà), 7/1
Ìrìn Àjò Gbé Wọn Pa Dà sí Ìgbà Àtijọ́ (Amish Lórílẹ̀-Èdè Amẹ́ríkà), 12/1
Ìrìn-Àjò Lọ sí ‘Abúlé Kan Tó Jìnnà Réré’ (Àgbègbè Sakha), 6/1
Irúgbìn Òtítọ́ Dé Àwọn Ibi Jíjìnnà Réré (Àgbègbè Tuva Nílẹ̀ Rọ́ṣíà), 7/15
Iṣẹ́ Ìwàásù àti Ìkọ́nilẹ́kọ̀ọ́ Nílẹ̀ Áfíríkà, 3/1
‘Jèhófà Ti Mú Kí Ojú Rẹ̀ Tàn sí Wọn Lára’ (àwọn adití), 8/15
Máa Ṣìkẹ́ Àwọn Ará Tó Jẹ́ Adití,11/15
Ǹjẹ́ O Lè Ré Kọjá Lọ sí Makedóníà? 12/15
Ó Láyọ̀ Ó sì Nírètí Bí Kò Tiẹ̀ Lówó Lọ́wọ́, 9/1
Ó Rí Àwọn Ìṣúra Tó Wà ní Ìpamọ́ (Estonia), 8/15
Ọmọdébìnrin Tó Jẹ́ Ọ̀làwọ́, 11/15
Ṣé Ẹlẹ́sìn Pùròtẹ́sítáǹtì Ni Wọ́n? 11/1
Ṣé O Lè Sìn Níbi Tí Wọn Ti Nílò Oníwàásù? 4/15, 12/15
BÍBÉLÌ
Àwọn Àfiwé Ọ̀rọ̀, 5/1
Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìṣípayá—Apá Kìíní, 1/15
Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìṣípayá—Apá Kejì, 2/15
Bó O Ṣe Lè Lóye Rẹ̀, 7/1
Ìdí Tí Wọ́n Fi Kọ Apá Kan Lédè Gíríìkì, 4/1
Ìwé Àfọwọ́kọ Vatican, 10/1
Kò Pa Run, 11/1
Ó Dé Erékùṣù Madagásíkà, 12/15
Ó Ń Yí Ìgbésí Ayé Èèyàn Pa Dà, 2/1, 7/1, 8/1, 11/1
Ó Wúlò, 6/1
Ó Yè Lédè Tó Ń Kú Lọ, 4/1
Ṣó Pọn Dandan Kó O Kọ́ Hébérù àti Gíríìkì? 11/1
Wọ́n Fẹ́ràn Rẹ̀, 6/1
Wọ́n Ṣàwárí Bíbélì Tó Ṣeyebíye (Codex Ephraemi Syri rescriptus), 9/1
ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI
Ààwẹ̀ Gbígbà, 4/1
Àwọn Àdúrà Tí Ọlọ́run Kì Í Dáhùn, 1/1
Àwọn Àdúrà Tí Ọlọ́run Ń Gbọ́, 2/1
Bẹ́ Ẹ Ṣe Lè Máa Ṣọ́wó Ná, 8/1
Bí Ọkọ Tàbí Aya Rẹ Bá Nílò Àbójútó Àrà Ọ̀tọ̀, 11/1
Èló Ló Yẹ Kí N Fi Ṣètọrẹ? 8/1
Èmi Ló Yẹ Kí Pinnu Ẹ̀sìn Mi Àbáwọn Òbí Mi? 9/15
Ẹ̀yin Ọkọ, Ẹ Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Ìfẹ́ Kristi, 5/15
Fi Ìfaradà Ṣe Iṣẹ́ Ìwàásù, 3/15
Fífasẹ́lénilọ́wọ́, 6/15
Fífúnni Ní Nǹkan Látọkàn Wá, 11/15
Ibi Tó Yẹ Kó O Wà Nígbà Tí Òpin Bá Dé, 5/15
Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Ń Mú Ìtẹ̀síwájú Wá, 7/15
“Ìgbà Dídákẹ́,” 5/15
Ìgbésí Ayé Ìdílé, 11/1
Ìsìnkú, 2/15
Ítítáì, 5/15
Jẹ́ Kí Ọlọ́run BÁ Ọ Sọ̀rọ̀ Lójoojúmọ́, 8/1
Láyọ̀ Láìlọ́kọ Tàbí Aya, 6/15
Má Gbàgbé Jèhófà, 3/15
Má Ṣe Jẹ́ Kí Ọkàn Rẹ Pínyà, 8/15
Máa Fi Ìmoore Hàn, Máa Fúnni Tọkàntọkàn, 7/15
Máa Láyọ̀ Nínú Iṣẹ́ Ọlọ́run Bí Ọwọ́ Rẹ Tiẹ̀ Dí, 12/15
Màríà, 1/1
Ọmọ Títọ́, 2/1
‘Ọ̀nà Ìfẹ́ Títayọ Ré Kọjá,’ 7/15
Ríran Ọmọ Tó Ń Bàlágà Lọ́wọ́, 5/1
Ṣé O Ti Sìn Nígbà Kan Rí? 8/15
Ṣé Ó Yẹ Kó O Rin Kinkin Mọ́ Ohun Tó Wù Ọ́? 2/15
Ṣó Yẹ Kí Obìnrin Tó Ń Túmọ̀ Àsọyé sí Èdè Àwọn Adití Bo Orí? 11/15
Tí Wọ́n Bá Ṣohun Tó Dùn Ọ́, 9/1
ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ
Àádọ́rùn-ún Ọdún Sẹ́yìn Ni Mo Bẹ̀rẹ̀ (E. Ridgwell), 7/15
“Áńgẹ́lì Jèhófà Dó Yí Àwọn Tí Ó Bẹ̀rù Rẹ̀ Ká” (C. Connell), 3/15
Àpéjọ Mẹ́ta Yí Ìgbésí Ayé Mi Pa Dà (G. Warienchuck), 10/15
Èèyàn Ò Gbọ́dọ̀ Wà Láàyè Nípa Oúnjẹ Nìkan (J. Hisiger), 3/1
“Èyí Ni Ọ̀nà. Ẹ Máa Rìn Nínú Rẹ̀” (E. Pederson látọwọ́ R. Pappas), 1/15
Kí Ni Mo Lè San Pa Dà fún Jèhófà? (R. Danner), 6/15
Mo Rí Ohun Rere Gbé Ṣe Nígbèésí Ayé Mi (G. Martínez), 9/15
Ó Láyọ̀ Láìka Àìlera Sí (P. Gaspar), 5/1
Ọpẹ́ Rẹ̀ Pọ̀ Láìka Àjálù Sí (E. Acosta), 6/1
JÈHÓFÀ
Àwọn Aláṣẹ Kátólíìkì Fẹ́ Pa Orúkọ Ọlọ́run Rẹ́, 4/1
Baba Àwọn Ọmọ Aláìníbaba, 4/1
Bẹ̀rù Ọlọ́run Dípò Èèyàn, 3/1
Bí Òun àti Jésù Ṣe Jẹ́ Ọ̀kan, 9/1
Ẹ̀rí Tó Ta Yọ Jù Lọ Pé Ó Nífẹ̀ẹ́ Wa, 2/1
Kí Ni Jèhófà Ń Béèrè Lọ́wọ́ Wa? 10/1
Má Gbàgbé Jèhófà, 3/15
“Mo Mọ Ìrora Tí Wọ́n Ń Jẹ” (Ẹk 3:1-10), 3/1
Ó Bìkítà, 6/1
Ó Fẹ́ Ká Ṣàṣeyọrí, 12/1
Ó Fún Wa Lómìnira Láti Yàn, 11/1
Ó Jẹ́ Mímọ́, 7/1
Ó Mọbi Tágbára Wa Mọ, 6/1
Ó Nífẹ̀ẹ́ Ọlọ́kàn Tútù, 8/1
Ó Ṣàpèjúwe Irú Ẹni Tó Jẹ́, 5/1
Onídàájọ́ Tó Máa Ń Ṣohun Tó Tọ́ Nígbà Gbogbo, 1/1, 9/1
Ọlọ́run Nìkan Ló Lè Tún Ayé Yìí Ṣe, 1/1
Ṣé Ààwẹ̀ Gbígbà Ló Máa Jẹ́ Kó O Sún Mọ́ Ọn? 4/1
Ṣé Jésù Ni? 2/1, 4/1
Ṣé Ó Fọwọ́ Sí Ìkóbìnrinjọ? 7/1
Ṣé Ó Ń Fi Ìṣòro Jẹ Wá Níyà? 6/1
Ṣé Ó Ń Pa Àwọn Ọmọdé Kó Lè Sọ Wọ́n Di Áńgẹ́lì? 3/1
Ṣé Ó Ń Yíhùn Pa Dà? 6/1
Ṣé Ó Ṣèlérí Ọrọ̀? 9/1
Ta Ni Ọlọ́run? 2/1
Yóò Fòpin Sí Ìjìyà! 12/1
JÉSÙ KRISTI
Àwọn Farisí Dà Bí “Àwọn Sàréè Tí A Kùn Lẹ́fun,” 11/1
Bí Òun àti Bàbá Ṣe Jẹ́ Ọ̀kan, 9/1
Ìdí Tí Ẹ̀wù Àwọ̀tẹ́lẹ̀ Rẹ̀ Fi Wu Àwọn Ọmọ Ogun, 7/1
Ìdí Tó Fi Sọ Pé, “Ábà, Baba” sí Jèhófà, 4/1
Ìdí Tí Jósẹ́fù Fi Fẹ́ Láti Kọ Màríà Sílẹ̀, 12/1
Ìkànìyàn Tó Wáyé Lákòókò Tí Wọ́n Bí I ní Bẹ́tílẹ́hẹ́mù, 12/1
Kí Nìdí Tó Fi Fọ Ẹsẹ̀ Àwọn Àpọ́sítélì? 1/1
Ó Borí Ìdẹwò, 5/1
Ohun Tó Kọ́ni Nípa “Àkókò Òpin,” 5/1
Ohun Tó Kọ́ni Nípa Àwọn Àdúrà Tí Ọlọ́run Ń Gbọ́, 2/1
Ohun Tọ́ Kọni Nípa Ìgbésí Ayé Ìdílé, 11/1
Ohun Tó Kọ́ni Nípa Ọjọ́ Ọ̀la Aráyé, 8/1
Ṣé Òótọ́ Ni Àwọn Amòye Mẹ́ta Lọ Wò Ó Nígbà Tó Wà Ní Ọmọ Ọwọ́? 12/1
Ṣé Òun Ni Ọlọ́run? 2/1, 4/1
Ọ̀KAN Ò JỌ̀KAN
Ààbò Lọ́wọ́ Àwọn Ẹ̀mí Búburú, 5/1
Àlàáfíà Nínú Ayé Oníwàhálà, 7/1
“Àmín,” 6/1
Àpótí Májẹ̀mú, 9/1
Àwọn Akọ̀wé Òfin Tó Ta Ko Jésù, 8/1
Àwọn Bàbá Ìjọ, 7/1
Àwọn Júù “gbé ìgbésẹ̀ ní àìmọ̀” (Iṣe 3:17), 6/15
Àwọn Ọkùnrin Tó Ń Jẹ́ Jákọ́bù, 9/1
Àwọn Ọmọ Ísírẹ́lì Awòràwọ̀, 3/1
“Àwọn Ọmọ Súúsì” (Iṣe 28:11), 3/1
Àtúnbí, 4/1
Bí Wọ́n Ṣe Pàdánù Párádísè, 11/1
Ẹ̀kọ́ Èké Mẹ́fà Tí Wọ́n Mú Wọnú Ìsìn Kristẹni, 11/1
Ẹ̀kọ́ Tí Òwe 24:27 Kọ́ Wa, 10/15
Ẹ̀mí Mímọ́—Ìdí Térò Kò Fi Ṣọ̀kan, 10/1
Ẹni Tó Gba Ìlérí Ọlọ́run Gbọ́ (Ábúráhámù), 7/1
Ẹ̀tẹ̀ Nínú Bíbélì, 2/1
“Hẹ́rọ́dù Ọba,” 12/1
Ìdí Táwọn Alágbẹ̀dẹ Fàdákà Fi Gbaná Jẹ Nígbà Tí Pọ́ọ̀lù Wàásù Nílùú Éfésù, 2/1
Igi ‘Tí Ẹ̀ka Rẹ̀ Kì Í Rọ,’ 3/1
Ìgbà Wo Ni Wọ́n Lé Sátánì Kúrò Lọ́run? 5/15
Ìgbàgbọ́ Tó Túbọ̀ Lágbára, 5/1
Ìjọsìn Báálì àti Ọ̀rọ̀ Ìṣekúṣe, 11/1
Ìjọsìn Ìdílé, 10/15
Ilé Là Ń Wò Ká Tó Sọmọ Lórúkọ, 2/1
Ìpakúpa Lọ́gbà Iléèwé, 12/1
Iṣẹ́ Ẹja Pípa Lórí Òkun Gálílì, 10/1
Ìtumọ̀ Ìfòróróyanni, 8/1
Ìwé “Jáṣárì,” Ti “Àwọn Ogun Jèhófà,” 3/15
Ìwòsàn Lọ́nà Ìyanu, 5/1
Ìyanu Ṣẹlẹ̀ Lọ́jọ́ Pẹ́ńtíkọ́sì, 9/1
Jèhóáṣì, 4/1
Jeremáyà, 12/1
Jòsáyà, 2/1
Kádàrá, 3/1
“Kí Ni A Ó Jẹ?” 8/1
Kọ́ríńtì, 3/1
Lásárù Jíǹde, 3/1
Mímọ Ìsìn Tòótọ́, 8/1
Ó Gbógun Ti Ìbẹ̀rù àti Iyèméjì (Pétérù), 10/1
Ó Hùwà Ọgbọ́n (Ábígẹ́lì), 7/1
Ó Kọ́ Béèyàn Ṣe Lè Jẹ́ Aláàánú (Jónà), 4/1
Ó Kọ́gbọ́n Látinú Àṣìṣe Ara Rẹ̀ (Jónà), 1/1
Ohun Gbogbo Làkókò Wà Fún, 3/1
Òjò, 1/1
“Olórí Ẹ̀ṣọ́ Tẹ́ńpìlì,” 10/1
Ọ̀dọ́ Kan Tó Nígboyà (Dáfídì), 1/1
Ọdún Tuntun (Éṣíà), 12/1
Ọmọkùnrin Tó Gba Ẹ̀mí Pọ́ọ̀lù Là, 6/1
Ọ̀nà Abẹ́lẹ̀ Ti Hesekáyà, 5/1
Ọwọ́ Tí Dáfídì Ọba Fi Mú Orin Kíkọ, 12/1
Ráhábù, 8/1
Ṣáwọn Míṣọ́nnárì Dé Ìpẹ̀kun Ìlà Oòrùn Ayé? 1/1
Ṣé Àjíǹde Wà Fọ́mọ Tó Kú Sínú Ìyá Rẹ̀? 4/15
Ṣé Eéṣú Wà Lára Oúnjẹ Látijọ́? (Mt 3:4), 10/1
Ṣé Ẹni Gidi Ni Èṣù? 10/1
Ṣé Ọlọ́run Kan Ni Gbogbo Wa Ń Sìn? 6/1
Ṣé Ọlọ́run Ti Kádàrá Wa? 4/1
Ṣé Wọ́n Fi Òpó Igi Olórí Ṣóńṣó Yí Jerúsálẹ́mù Ká? 5/1
Ṣé Wọ́n Ń Sin Oyin Ní Ísírẹ́lì Àtijọ́? 7/1
Ṣé Wọ́n Rí Ọkọ Nóà? 7/1
Ṣémù, 10/1
Ṣẹ́ni Gidi Ni Ádámù àti Éfà? 9/1
Ṣó O Máa Ń Bẹ̀rù Òkú? 1/1
Ṣó Ṣeé Ṣe Láti Nígbàgbọ́ Nínú Ẹlẹ́dàá? 10/1
Ṣó Yẹ Káwọn Kristẹni Máa Jagun? 10/1
Ṣó Yẹ Kí Pílátù Bẹ̀rù Késárì? 1/1
‘Ta Gbòǹgbò sì Fìdí Múlẹ̀ Lórí Ìpìlẹ̀ Náà,’ 10/15
Úrímù àti Túmímù, 6/1
Ya Àkókò Sọ́tọ̀ fún Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì, 10/15